Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 32

Àwọn ̀ìkọjá odò Jordani

1 Àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, wọ́n ẹran ̀sìn àti ohun ̀sìn ilẹ̀ Jaseri àti Gileadi dára fún ohun ̀sìn. 2 Àwọn ọmọ Gadi àti àwọn ọmọ Reubeni , wọ́n ̀dọ̀ Mose àti Eleasari àlùfáà àti olórí gbogbo ìlú, wọ́n , 3 "Atarotu, Diboni, Jaseri, Nimra, Heṣboni, Eleale, Sebamu, Nebo, àti Beoni. 4 Ni ilẹ̀ Olúwa ti ṣẹ́gun níwájú ìjọ Israẹli ó dára fún ohun ̀sìn, ṣáwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ohun ̀sìn." 5 Wọ́n , "a ojúrere rẹ, jẹ́ a fi ilẹ̀ yìí fún ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ ìní. ṣe jẹ́ a rékọjá odò Jordani."

6 Mose sọ fún àwọn ọmọ Gadi àti fún ọmọ Reubeni , "Ṣé àwọn arákùnrin yín lọ ogun, ̀yin ó jókòó ? 7 ni ó o fi ìrẹ̀wẹ̀àwọn ọmọ Israẹli láti lọ ibi ilẹ̀ Olúwa ti fi fún wọn? 8 32.8,9: Nu 13.17-33.Èyí ni nǹkan baba yín ṣe nígbà mo rán wọn láti Kadeṣi-Barnea láti lọ wo ilẹ̀ náà. 9 Lẹ́yìn ìgbà wọ́n lọ àfonífojì Eṣkolu wọ́n ilẹ̀ náà, wọ́n ìrẹ̀wẹ̀àwọn ọmọ Israẹli láti wọ ilẹ̀ Olúwa ti fi fún wọn. 10 32.10-13: Nu 14.26-35.Ìbínú Olúwa dìde wọn ọjọ́ náà, ó búra, , 11 Nítorí wọn tẹ̀mi tọkàntọkàn, í ṣe ̀kan nínú àwọn ọkùnrin náà ó jẹ́ ogún ọdún tàbí bẹ́̀ lọ ó gòkè láti Ejibiti ni yóò ilẹ̀ mo pinnu gẹ́gẹ́ ìbúra fún Abrahamu, fún Isaaki àti fún Jakọbu: 12 ẹnìkankan àyàfi Kalebu ọmọ Jefunne ti Kenissiti àti Joṣua ọmọ Nuni, nítorí wọ́n tẹ̀Olúwa tọkàntọkàn.13 Ìbínú Olúwa ru àwọn ọmọ Israẹli ó wọn rìn aginjù fún ogójì ọdún, títí àwọn ìran wọ́n ṣe búburú ojú rẹ̀ fi lọ.

14 "Níbí ni ̀yin , ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀, ̀yin dìde ipò baba yín, jẹ́ ìbínú gbígbóná Olúwa ru Israẹli. 15 ̀yin yípadà ̀yìn rẹ̀ yóò fi àwọn ènìyàn wọ̀nyí sílẹ̀ aginjù, ìwọ yóò un ṣe ìparun."

16 Nígbà náà wọ́n òkè ̀dọ̀ rẹ̀, "Àwa yóò fẹ́ láti kọ́ ilé ẹran níhìn-ín yìí fún ohun ̀sìn wa, àti ìlú fún àwọn obìnrin àti ọmọ wẹ́wẹ́ wa. 17 Ṣùgbọ́n àwa ṣetán láti dira ogun ṣáájú àwọn ọmọ Israẹli títí a yóò fi wọn ̀dọ̀ wọn lákokò yìí, àwọn obìnrin àti ọmọ wẹ́wẹ́ wa yóò gbé inú ìlú a mọ odi fún ìdáàbòbò wọn lọ́wọ́ olùgbé ilẹ̀ náà. 18 A yóò padà ilẹ̀ wa láìṣe gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ti gba ogún wọn. 19 A yóò gba ogún kankan pẹ̀wọn òdìkejì Jordani, nítorí ogún ti wa, ti ̀dọ̀ wa ìhà ìlà-oòrùn Jordani."

20 Nígbà náà ni Mose sọ fún wọn , "̀yin yóò pa ara yín lára, níwájú Olúwa fún ogún. 21 gbogbo yín yóò lọ Jordani ìhámọ́ra níwájú Olúwa, títí yóò fi àwọn ̀rẹ̀ kúrò níwájú rẹ̀. 22 a ó fi ṣe ilẹ̀ náà níwájú Olúwa; ̀yin padà yóò di òmìnira lọ́wọ́ ìdè níwájú Olúwa àti Israẹli. Ilẹ̀ yìí yóò jẹ́ tiyín níwájú Olúwa.

23 "Ṣùgbọ́n ̀yin kọ̀ láti ṣe èyí, ̀yin yóò máa dẹ́ṣẹ̀ Olúwa; ̀yin ó mọ̀ dájú ̀ṣẹ̀ yín yóò fi yín hàn. 24 kọ́ ilé fún àwọn obìnrin yín àti ọmọ wẹ́wẹ́ yín, àti ilé fún agbo ẹran yín, ṣùgbọ́n ̀yin ó ṣe ohun ti pinnu."

25 Àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni sọ fún Mose , "Àwa ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe gẹ́gẹ́ olúwa wa ti pàṣẹ. 26 Àwọn ọmọ wa àti ìyàwó wa, àwọn agbo ẹran àti ohun ̀sìn wa yóò dúró ìlú Gileadi. 27 Ṣùgbọ́n àwọn ìránṣẹ́ rẹ, gbogbo ọkùnrin ó wọ ìhámọ́ra ogun, yóò rékọjá lọ láti níwájú Olúwa; gẹ́gẹ́ olúwa wa ti sọ."

28 Nígbà náà ni Mose pàṣẹ nípa wọn fún Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni àti gbogbo olórí ìdílé ̀Israẹli. 29 Mose fún wọn , "àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni, gbogbo ọkùnrin ó wọ ìhámọ́ra fún ogun rékọjá odò Jordani pẹ̀níwájú Olúwa, nígbà ṣẹ́gun ilẹ̀ náà níwájú yín, fún wọn ilẹ̀ Gileadi gẹ́gẹ́ ìní wọn. 30 Ṣùgbọ́n wọn fẹ́ yín rékọjá pẹ̀ìhámọ́ra, wọn gbọdọ̀ gba ìní wọn pẹ̀yín Kenaani."

31 Àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni dáhùn , "Ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe ohun Olúwa ti sọ. 32 A máa rékọjá níwájú Olúwa lọ Kenaani pẹ̀ìhámọ́ra, ṣùgbọ́n ẹrù a jogún yóò ̀Jordani."

33 Nígbà náà Mose fún àwọn ọmọ Gadi àti àwọn ọmọ Reubeni àti ààbọ̀ ̀Manase ọmọ Josẹfu ilẹ̀ ọba Sihoni ọba àwọn ọmọ Amori àti ilẹ̀ ọba Ogu ọba Baṣani gbogbo ilẹ̀ náà pẹ̀ìlú rẹ̀ àti agbègbè ó i ka.

34 Àwọn ará Gadi wọ́n kọ́ Diboni, Atarotu, Aroeri; 35 pẹ̀Atrotu Ṣofani, Jaseri, àti Jogbeha, 36 pẹ̀Beti-Nimra, àti Beti-Harani ìlú olódi, àti agbo fún àgùntàn. 37 Àwọn ọmọ Reubeni kọ́ Heṣboni, Eleale, Kiriataimu, 38 pẹ̀Nebo pẹ̀Baali-Meoni (wọ́n pàrọ̀ orúkọ wọn) àti Sibma. Wọ́n sọ ìlú wọ́n tún kọ́ orúkọ mìíràn.

39 Àwọn ọmọ Makiri ọmọ Manase lọ Gileadi, wọ́n àwọn ọmọ Amori ó níbẹ̀. 40 Mose fi àwọn ọmọ Gileadi fún àwọn ọmọ Makiri àwọn ìran Manase, wọ́n tẹ̀síbẹ̀. 41 Jairi, ọmọ Manase gba ibùjókòó wọn, ó wọ́n Haffotu Jairi. 42 Noba gba Kenati àti àwọn ìtẹ̀rẹ̀, ó é Noba lẹ́yìn orúkọ ara rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também