Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 36

Ogún ọmọbìnrin Selofehadi

1 Àwọn olórí ìdílé Gileadi, ọmọkùnrin Makiri ọmọ Manase ó láti ara ìdílé ìran Josẹfu , wọ́n sọ̀rọ̀ níwájú Mose àti àwọn olórí, àwọn ìdílé Israẹli. 2 36.2: Nu 27.7.Wọ́n sọ , "Nígbà Olúwa pàṣẹ fún olúwa mi láti fi ilẹ̀ yìí fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ ogún nípa kèké ṣíṣẹ́. Ó pa á láṣẹ fún láti fi ogún Selofehadi arákùnrin wa fún àwọn ọmọbìnrin rẹ̀. 3 Wàyí, wọn fẹ́ ọkùnrin láti ̀Israẹli mìíràn; nígbà náà a ó gba ogún un wọn kúrò nínú ogún ìran wa, a ó fi kún ogún ̀a fẹ́ wọn . Bẹ́̀ ni a ó gbà á kúrò nínú ìpín ilẹ̀ ogún ti wa. 4 Nígbà ọdún ìdásílẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli , a ó pa ogún wọn pọ̀ mọ́ ̀wọ́n fẹ́ wọn , a ó gba ogún ̀wọn kúrò lọ́wọ́ baba ńlá wọn."

5 Gẹ́gẹ́ àṣẹ Olúwa, Mose pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli , "Ohun ti ̀àwọn ìran Josẹfu ń sọ tọ̀. 6 Èyí ni ohun Olúwa pàṣẹ fún àwọn ọmọbìnrin Selofehadi: wọ́n fẹ́ ẹni ọkàn wọn fẹ́, kìkì wọ́n fẹ́ nínú ̀ìdílé baba wọn. 7 ogún kan Israẹli ó gbọdọ̀ kọjá láti ̀kan ̀mìíràn, nítorí gbogbo ọmọ Israẹli ni yóò fi ilẹ̀ ogún ̀wọ́n jogún láti ̀dọ̀ baba ńlá wọn pamọ́. 8 Gbogbo ọmọbìnrin ó jogún ilẹ̀ nínú ̀Israẹli kọ̀̀kan gbọdọ̀ fẹ́ ènìyàn nínú ̀ìdílé baba rẹ̀, gbogbo ọmọ Israẹli ìpín nínú ogún baba wọn. 9 ogún kankan ó gbọdọ̀ kọjá láti ̀kan ̀òmíràn, nítorí olúkúlùkù ̀ọmọ Israẹli gbọdọ̀ tọ́ilẹ̀ ó jogún."

10 Nígbà náà, àwọn ọmọbìnrin Selofehadi ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti pa á láṣẹ fún Mose. 11 Nítorí a gbé Mahila, Tirsa, Hogla, Milka, àti Noa, àwọn ọmọbìnrin Selofehadi ìyàwó fún àwọn ọmọ arákùnrin baba wọn. 12 Wọ́n fẹ́ ọkọ nínú ìdílé ìran Manase, ọmọ Josẹfu ogún wọn nínú ìdílé àti ̀baba wọn.

13 Wọ̀nyí ni àṣẹ àti ìdájọ́ Olúwa ti ipasẹ̀ Mose fún àwọn ọmọ Israẹli pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu lẹ́bàá Jordani létí Jeriko.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também