Pular para o conteúdo
Publicidade

Ẹkún Jeremiah 1

1 Báwo ni ìlú ṣe jókòó nìkan,

nígbà kan ó kún fún ènìyàn!

Ó ti fìgbà kan jẹ́ ìlú olókìkí láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

ó ipò opó,

ẹni ó jẹ́ ọmọ ọbabìnrin láàrín ìlú

ni ó padà di ẹrú.

2 ̀gànjọ́ òru ni ó fi máa ń sọkún kíkorò

pẹ̀omijé ̀rẹ̀kẹ́ rẹ̀ ó dúró ̀rẹ̀kẹ́ rẹ̀.

Nínú gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ̀

̀kan nínú wọn láti rẹ̀ ́ lẹ́kún.

Gbogbo àwọn ̀rẹ́ rẹ̀ ti jọ̀wọ́ rẹ̀

wọ́n ti di alátakò rẹ̀.

3 Lẹ́yìn ìjìyà àti ìpọ́njú nínú oko ẹrú,

Juda lọ àjò

Ó tẹ̀láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

ṣùgbọ́n ibi ìsinmi.

Àwọn ó ń tẹ̀á mọ́

ibi ti le àsálà.

4 Gbogbo ̀ó wọ Sioni ń ṣọ̀fọ̀,

nítorí ẹnìkan àjọ̀dún a yàn.

Gbogbo ẹnu-bodè rẹ̀ dahoro,

àwọn àlùfáà rẹ̀ kẹ́dùn,

àwọn wúńdíá rẹ̀ ń káàánú,

òun gan an ọkàn kíkorò.

5 Àwọn aninilára rẹ̀ gbogbo di olúwa rẹ̀,

nǹkan rọrùn fún àwọn ̀rẹ̀,

Olúwa ti fún un ìjìyà tọ́

nítorí àwọn ̀ṣẹ̀ rẹ̀.

Àwọn ̀ṣọ́ wẹ́wẹ́ rẹ̀ lọ oko ẹrú,

ìgbèkùn níwájú àwọn ̀.

6 Gbogbo ẹwà ti di ohun ìgbàgbé

kúrò lọ́dọ̀ ọmọbìnrin Sioni.

Àwọn ìjòyè rẹ̀ dàbí i àgbọ̀nrín

ewé tútù jẹ;

nínú àárẹ̀ wọ́n sáré

níwájú ẹni ó ń wọn.

7 ọjọ́ ìpọ́njú àti àrìnká rẹ̀ ni

Jerusalẹmu rántí àwọn ohun ìní dáradára rẹ̀

ó jẹ́ tirẹ̀ ọjọ́ pípẹ́.

Nígbà àwọn ènìyàn rẹ̀ ṣubú ṣọ́wọ́ àwọn ̀,

ṣí olùrànlọ́wọ́ fún un.

Àwọn ̀rẹ̀ ó

wọ́n ń fi ìparun rẹ̀ ṣẹlẹ́.

8 Jerusalẹmu ti dẹ́ṣẹ̀ púpọ̀

ó ti di aláìmọ́.

Àwọn ó ń tẹríba fún un kẹ́gàn rẹ̀,

nítorí wọ́n ti ìhòhò rẹ̀;

ó kérora fúnra rẹ̀,

ó lọ kúrò.

9 Ìdọ̀etí aṣọ rẹ̀,

bẹ́̀ ni wo ọjọ́ iwájú rẹ̀.

Ìṣubú rẹ̀ ya ni lẹ́nu;

olùtùnú ṣí fún un.

"Wo ìpọ́njú mi, Olúwa,

nítorí àwọn ̀ti borí."

10 ̀ti gbọ́wọ́

gbogbo ìní rẹ;

o àwọn orílẹ̀-èdè

wọ́n wọ ibi mímọ́ rẹ

àwọn o ti kọ̀sílẹ̀

láti wọ ìpéjọpọ̀ rẹ.

11 Àwọn ènìyàn rẹ̀ ń kérora

wọ́n ti ń oúnjẹ;

wọ́n fi ohun ìní wọn ṣe pàṣípàrọ̀ oúnjẹ

láti wọn láààyè.

"ó, Olúwa, o ó,

nítorí a kọ̀ sílẹ̀."

12 "ha jẹ́ nǹkan kan i yín?

Gbogbo ̀yin ń rékọjá.

Ǹjẹ́ ẹnìkan ń jìyà èmi ti ń jìyà

a fi fún mi, ti

Olúwa fún mi

ọjọ́ ìbínú gbígbóná rẹ̀.

13 "Ó rán iná láti òkè

sọ̀kalẹ̀ sínú egungun ara mi.

Ó dẹ àwọ̀n fún ẹsẹ̀ mi,

ó mi padà.

Ó ti pa lára

ń lọ gbogbo ọjọ́.

14 "̀ṣẹ̀ mi ti di sísopọ̀ àjàgà;

ọwọ́ rẹ̀ ni a fi hun ún papọ̀.

Wọ́n ti ọrùn mi

Olúwa ti dín agbára mi .

Ó ti fi

àwọn n le dojúkọ lọ́wọ́.

15 "Olúwa kọ

àwọn akọni mi sílẹ̀,

ó rán àwọn ológun lòdì mi

wọn pa àwọn ̀dọ́mọkùnrin mi run.

Nínú ìfúntí wáìnì rẹ̀ Olúwa tẹ́

àwọn ̀dọ́mọbìnrin Juda.

16 "Ìdí nìyí mo fi ń sọkún

omijé ń lójú mi.

Olùtùnú àti ẹni ó le ọkàn mi sọjí jìnnà mi,

ẹni yóò ̀mi padà.

Àwọn ọmọ mi di aláìní

nítorí ̀ti borí."

17 Sioni na ọwọ́ jáde,

ṣùgbọ́n olùtùnú fún un.

Olúwa ti pàṣẹ fún Jakọbu

àwọn ará ilé rẹ̀ di ̀fún un

Jerusalẹmu ti di

ohun aláìmọ́ láàrín wọn.

18 "Olóòtítọ́ ni Olúwa,

ṣùgbọ́n mo ṣọ̀tẹ̀ àṣẹ rẹ̀.

gbọ́, gbogbo ènìyàn;

ìyà mi.

Gbogbo ̀dọ́mọkùnrin àti ̀dọ́mọbìnrin mi

ni a ti lọ ìgbèkùn.

19 "Mo pe àwọn ̀rẹ́ mi

ṣùgbọ́n wọ́n .

Àwọn olórí àlùfáà àti àgbàgbà mi

ṣègbé sínú ìlú

nígbà wọ́n ń oúnjẹ

yóò wọn láààyè.

20 "Olúwa, ó, mo ti nínú ìnira!

mo ń jẹ̀rora nínú mi,

ìdààmú ọkàn mi

nítorí a ti ṣọ̀tẹ̀ mi gidigidi.

gbangba ni idà ń parun;

ikú nínú ilé pẹ̀.

21 "Àwọn ènìyàn ti gbọ́ ìrora mi,

ṣùgbọ́n olùtùnú fún mi.

Àwọn ̀mi ti gbọ́ ìparun mi;

wọ́n yọ̀ ohun o ṣe.

o ọjọ́ o ti kéde,

wọ́n le dàbí tèmi.

22 "Jẹ́ ìwà ìkà wọn síwájú rẹ;

jẹ wọ́n

o ṣe jẹ

nítorí gbogbo ̀ṣẹ̀ mi.

Ìrora mi pọ̀

ọkàn mi rẹ̀wẹ̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Lamentações
Ver todos os capítulos de Lamentações