Pular para o conteúdo
Publicidade

Nehemiah 5

Nehemiah ran àwọn aláìní lọ́wọ́

1 Nísinsin yìí àwọn ènìyàn àti àwọn ìyàwó wọn kígbe ńlá sókè àwọn Júù arákùnrin wọn. 2 Àwọn kan ń , "Àwa àti àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wa pọ̀; àwa ó le è jẹ, a láààyè, a gbọdọ̀ oúnjẹ."

3 Àwọn mìíràn , "Àwa ti fi oko wa ọgbà àjàrà wa àti ilé wa dógò àwa ó oúnjẹ àkókò ìyàn."

4 Síbẹ̀ àwọn mìíràn , "Àwa láti owó láti san ìṣákọ́lẹ̀ fún ọba lórí àwọn oko wa àti àwọn ọgbà àjàrà wa. 5 ó tilẹ̀ jẹ́ a jẹ́ ẹran-ara kan àti ̀jẹ̀ kan gẹ́gẹ́ àwọn ará ìlú wa àwọn ọmọkùnrin wa dára í tiwọn, síbẹ̀ àwa láti fi àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wa oko ẹrú. Díẹ̀ nínú àwọn ọmọbìnrin wa ti lóko ẹrú náà, ṣùgbọ́n àwa agbára, nítorí àwọn oko àti ọgbà àjàrà wa ti di ti ẹlòmíràn."

6 Èmi bínú gidigidi nígbà mo gbọ́ igbe wọn àti àwọn ̀sùn wọ̀nyí. 7 Mo wọ́n ọkàn mi mo fi ̀sùn kan ọlọ́àti àwọn ìjòyè. Mo sọ fún wọn , ̀yin ń gba owó èlé lọ́wọ́ àwọn ará ìlú u yín! Nítorí náà mo pe àpéjọ ńlá láti wọn . 8 Mo fún wọn , "Níbi àwa agbára mọ, àwa ti ra àwọn Júù arákùnrin wa a ti fún àwọn í ṣe Júù padà. Nísinsin yìí ̀yìn ń ta àwọn arákùnrin yín, àwa tún láti wọ́n padà!" Wọ́n dákẹ́, nítorí wọn ohunkóhun sọ.

9 Nítorí náà, mo tẹ̀síwájú , "Ohun ̀ ń ṣe dára. ha yẹ máa rìn nínú ìbẹ̀Ọlọ́run , láti yẹra fún ̀gàn àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn í ṣe ̀wa? 10 Èmi àti àwọn arákùnrin mi àti àwọn ènìyàn mi, pẹ̀ń àwọn ènìyàn lówó àti oúnjẹ. Ṣùgbọ́n jẹ́ a dáwọ́ owó èlé gbígbà yìí dúró! 11 fún wọn oko wọn, ọgbà àjàrà wọn, ọgbà olifi wọn àti ilé e wọn pẹ̀owó èlé ti gbà lọ́wọ́ wọn ìdá ọgọ́rùn-ún owó, oúnjẹ, wáìnì tuntun àti òróró ti gbà lọ́wọ́ wọn padà kíákíá."

12 Wọ́n , "Àwa yóò a padà. Àwa yóò béèrè ohunkóhun lọ́wọ́ wọn mọ́. Àwa yóò ṣe o ti ."

Nígbà náà mo pe àwọn àlùfáà, mo àwọn ọlọ́àti àwọn ìjòyè búra láti jẹ́ wọ́n ṣe ohun wọ́n ti ṣe ìlérí. 13 Mo gbọn ìṣẹ́aṣọ mi, mo , "Báyìí ni Ọlọ́run gbọn olúkúlùkù ènìyàn pa ìlérí yìí mọ́ jáde kúrò ilẹ̀ ìní i rẹ̀. Bẹ́̀ ni a gbọn irú ẹni bẹ́̀ jáde ó ṣófo!"

Gbogbo ìjọ ènìyàn , "Àmín," wọ́n fi ìyìn fún Olúwa. Àwọn ènìyàn náà ṣe wọ́n ti ṣe ìlérí.

14 Síwájú í, láti ogún ọdún ọba Artasasta, nígbà a ti yàn láti jẹ́ baálẹ̀ wọn ilẹ̀ Juda, títí di ọdún kejìlélọ́gbọ̀n ìjọba rẹ̀—ọdún méjìlá, èmi àti àwọn arákùnrin mi jẹ oúnjẹ baálẹ̀. 15 Ṣùgbọ́n àwọn baálẹ̀ ìṣáájúó ti ṣáájú migbe àjàgà wúwo àwọn ènìyàn lórí yàtọ̀ fún oúnjẹ àti wáìnì wọ́n tún gba ogójì ṣékélì fàdákà lọ́wọ́ wọn. Kódà àwọn ìránṣẹ́ wọn tún jẹ gàba lórí wọn. Ṣùgbọ́n èmi ṣe bẹ́̀ nítorí ìbẹ̀Ọlọ́run. 16 Dípò bẹ́̀, mo fi ara mi fún iṣẹ́ lórí odi yìí. Gbogbo àwọn ènìyàn mi péjọ síbẹ̀ fún iṣẹ́ náà; a gba ilẹ̀ kankan.

17 Síwájú í, àádọ́jọ àwọn Júù àti àwọn ìjòyè jẹun lórí tábìlì mi, àti pẹ̀àwọn wọ́n wa láti àwọn orílẹ̀-èdè ó wa . 18 ọjọ́ kọ̀̀kan ni a máa ń pèsè màlúù kan, ààyò àgùntàn mẹ́àti adìyẹ fún mi àti lẹ́̀kan ọjọ́ mẹ́wàá ni wọ́n máa ń pèsè onírúurú wáìnì ó pọ̀ fún mi. Fún gbogbo èyí, èmi béèrè oúnjẹ baálẹ̀, nítorí ohun ti a ń béèrè lọ́wọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí pọ̀ jọjọ.

19 Rántí mi, Ọlọ́run mi, fún rere, nítorí fún gbogbo ohun mo ti ṣe fún àwọn ènìyàn yìí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também