Pular para o conteúdo
Publicidade

Nehemiah 7

1 Lẹ́yìn ìgbà a tún odi mọ tán mo ri àwọn ìlẹ̀kùn ààyè wọn, a yan àwọn aṣọ́bodè, àwọn akọrin àti àwọn Lefi. 2 Mo fún Hanani arákùnrin mi pẹ̀Hananiah olórí ilé ìṣọ́ àṣẹ lórí Jerusalẹmu, nítorí ó jẹ́ ènìyàn olóòtítọ́, ó bẹ̀Ọlọ́run ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ti ṣe lọ. 3 Mo sọ fún wọn , "A gbọdọ̀ ṣí ìlẹ̀kùn Jerusalẹmu títí oòrùn yóò fi . Nígbà àwọn aṣọ́bodè lẹ́nu iṣẹ́, jẹ́ wọn ti ìlẹ̀kùn wọn wọn. Bákan náà, yàn nínú àwọn ń gbé Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ olùṣọ́. Àwọn mìíràn níbi a pín wọn àti àwọn mìíràn tòsí ilé e wọn."

Àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn ìgbèkùn wọ́n padà

4 Ìlú náà tóbi ó ààyè, ṣùgbọ́n ènìyàn inú rẹ̀ kéré, a ì tún àwọn ilé inú rẹ̀ kọ́. 5 Nígbà náà ni Ọlọ́run mi fi mi ọkàn láti àwọn ọlọ́, àwọn ìjòyè, àti àwọn ènìyàn jọ fún ìforúkọsílẹ̀ ìdílé ìdílé. Mo ìwé àkọsílẹ̀ ìtàn ìran àwọn ó kọ́ gòkè padà láti ìgbèkùn. Èyí ni ohun mo a kọ sínú ìwé náà.

6 7.6-73: Es 2.1-70. Èyí ni àwọn ènìyàn agbègbè náà wọ́n sọ̀kalẹ̀ láti ìgbèkùn, àwọn Nebukadnessari ọba Babeli ti ìgbèkùn (wọ́n padà Jerusalẹmu àti Juda, olúkúlùkù ìlú u rẹ̀. 7 Wọ́n jọ rìn pẹ̀u Serubbabeli, Jeṣua, Nehemiah, Asariah, Raamiah, Nahamani, Mordekai, Bilṣani, Misperi, Bigfai, Nehumu, àti Baanah).

Àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn ọkùnrin Israẹli,

8 àwọn ọmọ

Paroṣi jẹ́ ẹgbàá ó méjìléláàádọ́sàn-án (2,172)

9 Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó méjìlá (372)

10 Arah jẹ́ ẹgbẹ̀tàléláàádọ́ta ó méjì (652)

11 Pahati-Moabu (láti ipasẹ̀ ọmọ Jeṣua àti Joabu) jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìnlá ó méjìdínlógún (2,818)

12 Elamu jẹ́ àádọ́ta lẹ́gbẹ̀ó mẹ́rin (1,254)

13 Sattu jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀rin ó márùn-ún (845)

14 Sakkai jẹ́ òjìdínlẹ́gbẹ̀rin (760)

15 Binnui jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀ta ó mẹ́jọ (648)

16 Bebai jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó méjìdínlọ́gbọ̀n (628)

17 Asgadi jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó dín méjìdínlọ́gọ́rin (2,322)

18 Adonikami jẹ́ ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó méje (667)

19 Bigfai jẹ́ ẹgbàá ó mẹ́tàdínláàádọ́rin (2,067)

20 Adini jẹ́ àádọ́ta lẹ́gbẹ̀ta ó márùn-ún (655)

21 Ateri (láti ipasẹ̀ Hesekiah) jẹ́ méjìdínlọ́gọ́rùn-ún (98)

22 Haṣumu jẹ́ ̀rìndínnírinwó ó mẹ́jọ (328)

23 Besai jẹ́ ̀rìndínnírinwó ó mẹ́rin (324)

24 Harifu jẹ́ méjìléláàádọ́(112)

25 Gibeoni jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùn (95).

26 Àwọn ọmọ

Bẹtilẹhẹmu àti Netofa jẹ́ igba ó dín méjìlélógún (188)

27 Anatoti jẹ́ méjìdínláàádóje (128)

28 Beti-Asmafeti jẹ́ méjìlélógójì (42)

29 Kiriati-Jearimu, Kefira, àti Beeroti jẹ́ ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó mẹ́ta (743)

30 Rama àti Geba jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó mọ́kànlélógún (621)

31 Mikmasi jẹ́ méjìlélọ́gọ́(122)

32 Beteli àti Ai jẹ́ mẹ́tàlélọ́gọ́(123)

33 Nebo mìíràn jẹ́ méjìléláàádọ́ta (52)

34 Elamu mìíràn jẹ́ ẹgbẹ̀ó mẹ́rìnléláàádọ́ta (1,254)

35 Harimu jẹ́ ̀rìndínnírinwó (320)

36 Jeriko jẹ́ ̀tàdínnírinwó ó márùn-ún (345).

37 Lodi, Hadidi, àti Ono jẹ́ ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rin ó ̀kan (721)

38 Senaa jẹ́ ẹgbàajì ó dín àádọ́rin (3,930).

39 Àwọn àlùfáà:

àwọn ọmọ

Jedaiah (láti ipasẹ̀ ìdílé Jeṣua) jẹ́ ogún dín lẹ́gbẹ̀rin ó dín méje (973)

40 Immeri jẹ́ àádọ́ta lẹ́gbẹ̀rún ó méjì (1,052)

41 Paṣuri jẹ́ ẹgbẹ̀ó mẹ́tàdínláàádọ́ta (1,247)

42 Harimu jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó mẹ́tàdínlógún (1,017).

43 Àwọn ọmọ Lefi:

àwọn ọmọ

Jeṣua (láti ipasẹ̀ Kadmieli, láti ipasẹ̀ Hodafiah) jẹ́ mẹ́rìnléláàádọ́rin (74).

44 Àwọn akọrin:

àwọn ọmọ

Asafu jẹ́ méjìdínláàádọ́jọ (148).

45 Àwọn aṣọ́:

àwọn ọmọ

Ṣallumu, Ateri, Talmoni,

Akkubu, Hatita, àti Ṣobai jẹ́ méjìdínlógóje (138).

46 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili.

Àwọn ọmọ

Siha, Hasufa, Tabboati,

47 Kerosi, Sia, Padoni,

48 Lebana, Hagaba, Ṣalmai,

49 Hanani, Giddeli, Gahari,

50 Reaiah, Resini, Nekoda,

51 Gassamu, Ussa, Pasea,

52 Besai, Mehuni, Nefisimu,

53 Bakbu, Hakufa, Harhuri,

54 Basluti, Mehida, Harṣa,

55 Barkosi, Sisera, Tema,

56 Nesia, àti Hatifa.

57 Àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni:

àwọn ọmọ

Sotai, Sofereti; Perida,

58 Jaala, Darkoni, Giddeli,

59 Ṣefatia, Hattili,

Pokereti-Haṣṣebaimu, àti Amoni.

60 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ọmọ ìránṣẹ́ Solomoni jẹ́ irinwó ó dín mẹ́jọ (392).

61 Àwọn wọ̀nyí gòkè láti àwọn ìlú ti Teli-Mela, Teli-Harṣa, Kerubu, Addoni àti Immeri, ṣùgbọ́n wọn sọ pẹ̀ìdánilójú ìdílé àwọn láti ara ìran ̀Israẹli.

62 Àwọn ọmọ

Delaiah, Tobiah àti Nekoda jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀ta ó méjì (642).

63 Lára àwọn àlùfáà ni:

àwọn ọmọ

Hobaiah, Hakosi àti Barsillai (ọkùnrin ó fẹ́ ọmọbìnrin Barsillai ará Gileadi, ẹni a ń fi orúkọ yìí ).

64 Àwọn wọ̀nyí àkọsílẹ̀ orúkọ ìran wọn, ṣùgbọ́n wọn í níbẹ̀, fún ìdí èyí, a yọ wọ́n kúrò nínú àwọn ń ṣiṣẹ́ àlùfáà gẹ́gẹ́ aláìmọ́. 65 Baálẹ̀ sọ fún wọn nítorí náà wọn gbọdọ̀ kópa nínú jíjẹ oúnjẹ mímọ́ títí àlùfáà yóò ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀Urimu àti Tumimu yóò fi .

66 Gbogbo ìjọ ènìyàn náà jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó òjìdínnírinwó (42,360), 67 yàtọ̀ àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin wọ́n jẹ́ ẹgbẹ̀ta dín lẹ́gbàárin ó dín ̀tàlélọ́gọ́ta (7,337); wọ́n tún àwọn akọrin ọkùnrin àti obìnrin wọ́n jẹ́ òjìlúgba ó márùn-ún (245). 68 Ẹṣin wọn jẹ́ ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́rin (736), ìbákasẹ wọn jẹ́ òjìlúgba ó dín márùn-ún (245); 69 ìbákasẹ wọn jẹ́ òjìlénírinwó ó dín márùn-ún (435); kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọ́n jẹ́ ẹgbẹ̀rìnlélọ́gbọ̀n ó dín ọgọ́rin (6,720).

70 Díẹ̀ lára àwọn olórí ìdílé náà kópa nínú ṣíṣe iṣẹ́ náà. Baálẹ̀ fún ilé ìṣúra ẹgbẹ̀rún (1,000) dariki wúrà, àádọ́ta àwo koto àti ̀rìndínlẹ́gbẹ̀ta mẹ́wàá (530) ̀fún àwọn àlùfáà. 71 Díẹ̀ lára àwọn olórí ìdílé fún ilé ìṣúra ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) dariki wúrà àti ẹgbọ̀kànlá (2,200) mina fàdákà. 72 Àròpọ̀ gbogbo ohun àwọn ènìyàn tókù fi sílẹ̀ jẹ́ ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) dariki wúrà, ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) mina fàdákà àti ẹẹ́tàdínláàdọ́rin ̀fún àwọn àlùfáà.

73 Àwọn àlùfáà, àwọn Lefi, àwọn aṣọ́bodè, àwọn akọrin, àwọn ènìyàn díẹ̀, àwọn ìránṣẹ́ ilé Ọlọ́run, àti gbogbo ènìyàn Israẹli ìlú wọn.

Esra ka òfin

Nígbà ó di oṣù keje, àwọn ọmọ Israẹli ti nínú ìlú u wọn,

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também