Pular para o conteúdo
Publicidade

Nehemiah 13

Àtúnṣe ìkẹyìn Nehemiah ṣe

1 13.1: De 23.3-5. ọjọ́ náà ni a ka ìwé Mose sókè etí ìgbọ́ àwọn ènìyàn, nínú rẹ̀ ni a ti i a kọ ́ sílẹ̀ a gbọdọ̀ gba àwọn ará a Ammoni tàbí àwọn ará a Moabu àárín ìjọ ènìyàn Ọlọ́run láéláé. 2 Nítorí wọn oúnjẹ àti omi pàdé àwọn ọmọ Israẹli lọ́, dípò bẹ́̀, wọ́n bẹ Balaamu ̀wẹ̀ láti gégùn ún wọn lórí. (Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wa ègún náà padà ìbùkún.) 3 Nígbà àwọn ènìyàn gbọ́ òfin yìí, wọ́n yọ gbogbo àwọn àjèjì ènìyàn ó darapọ̀ mọ́ wọn kúrò láàrín àwọn Israẹli.

4 Ṣáájú èyí a ti fi Eliaṣibu àlùfáà ṣe alákòóso yàrá ìkó nǹkan ilé Ọlọ́run wa . Ó súnmọ́ Tobiah pẹ́kípẹ́. 5 Ó ti pèsè yàrá ńlá kan fún un, èyí a ń tẹ́lẹ̀ fún ìtọ́ọrẹ ọkà, tùràrí àti àwọn ohun èlò tẹmpili àti ìdámẹ́wàá ọkà, wáìnì tuntun àti òróró ti a fi lélẹ̀ ìlànà fún àwọn ọmọ Lefi, àwọn akọrin àti àwọn aṣọ́àti pẹ̀gbogbo ọrẹ fún àwọn àlùfáà.

6 Ṣùgbọ́n nígbà gbogbo èyí ń lọ lọ́wọ́, èmi Jerusalẹmu, nítorí ọdún kejìlélọ́gbọ̀n Artasasta ọba Babeli ni mo padà tọ ọba lọ. Ṣùgbọ́n nígbà ó ṣe díẹ̀, mo gba ààyè lọ́dọ̀rẹ̀. 7 Mo padà Jerusalẹmu. Níhìn-ín ni mo ti mọ̀ nípa onírúurú ohun búburú Eliaṣibu ti ṣe ti pípèsè yàrá fún Tobiah nínú àgbàlá ilé Ọlọ́run. 8 tẹ́ mi lọ́rùn rárá, mo gbogbo ohun èlò ìdílé e Tobiah síta láti inú iyàrá náà. 9 Mo pàṣẹ wọn ya àwọn iyàrá náà mímọ́, mo àwọn ohun èlò ilé Ọlọ́run padà síbẹ̀ pẹ̀ọrẹ ọkà àti tùràrí.

10 Mo tún gbọ́ , fi àwọn ìpín a sọ́tọ̀ fún àwọn Lefi, àwọn akọrin ń ṣe àkóso ìsìn ti padà ẹnu onírúurú iṣẹ́ wọn. 11 Nígbà náà ni mo àwọn ìjòyè , mo béèrè lọ́wọ́ wọn , "Èéṣe a fi kọ ilé Ọlọ́run sílẹ̀?" Nígbà náà ni mo wọ́n jọ pọ̀, mo fi olúkúlùkù ẹnu iṣẹ́ rẹ̀.

12 Gbogbo Juda ìdámẹ́wàá ọkà, wáìnì tuntun àti òróró sínú yàrá ìkó nǹkan pamọ́ . 13 Mo fi àlùfáà Ṣelemiah, Sadoku akọ̀àti ọmọ Lefi kan orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Pedaiah ṣe alákòóso àwọn yàrá ìkó nǹkan pamọ́ . Mo yan Hanani ọmọ Sakkuri, ọmọ Mattaniah olùrànlọ́wọ́ wọn. Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ni a àwọn ṣé e gbẹ́kẹ̀. Àwọn ni a yàn láti máa pín ohun èlò fún àwọn arákùnrin wọn.

14 Rántí ì mi fún èyí, Ọlọ́run mi, o ṣe gbàgbé ohun mo fi òtítọ́ ṣe fún ilé Ọlọ́run mi yìí àti fún iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo.

15 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, mo àwọn ènìyàn Juda wọ́n ń fúntí ọjọ́ ìsinmi, wọ́n ń gbé ọkà wọlé, wọn ń di ẹrù orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ pẹ̀wáìnì, èso àjàrà, ̀pọ̀tọ́ àti onírúurú ẹrù. Wọ́n ń gbogbo èyí Jerusalẹmu ọjọ́ ìsinmi. Nítorí náà, mo kìlọ̀ fún wọn nípa títa oúnjẹ ọjọ́ náà. 16 Àwọn ará Tire ti ń gbé nínú Jerusalẹmu ń gbé ẹja àti onírúurú ọjà fún títà ọjọ́ ìsinmi fún àwọn ènìyàn Jerusalẹmu àti fún àwọn ọmọ Juda. 17 Mo àwọn ọlọ́Juda , mo fún wọn , "Èwo ni ohun búburú ń ṣe yìí ti ń ba ọjọ́ ìsinmi jẹ́. 18 Ṣé àwọn baba ńlá yín ha ti ṣe nǹkan kan náà Ọlọ́run wa fi gbogbo àjálù yìí orí wa, àti sórí ìlú yìí? Báyìí, ̀yin tún ń ru ìbínú sókè i sórí Israẹli nípa bíba ọjọ́ ìsinmi jẹ́."

19 Nígbà ojú ọjọ́ ń bora ẹnu ibodè Jerusalẹmu, ṣáájú ọjọ́ ìsinmi, mo pàṣẹ a ti àwọn ìlẹ̀kùn, wọn ṣí i títí ọjọ́ ìsinmi yóò fi kọjá. Mo yan àwọn ìránṣẹ́ mi láti ṣọ́ ẹnu ibodè, a ba à gbé ẹrù kankan wọlé ọjọ́ ìsinmi. 20 Síbẹ̀, àwọn ń àti àwọn ń sùn ̀yìn odi Jerusalẹmu ̀̀kan tàbí ̀̀mejì. 21 Ṣùgbọ́n mo kìlọ̀ fún wọn , "Èétijẹ́ ti ̀yin fi ń sùn ̀yin odi òru? ̀yìn tún dánwò mọ́, èmi yóò fi ọwọ́ líle yín." Láti ọjọ́ náà lọ, wọn ọjọ́ ìsinmi mọ́. 22 Nígbà náà ni mo pàṣẹ fún àwọn ọmọ Lefi wọn ya ara wọn mímọ́, wọn ṣọ́ ẹnu ibodè a pa ọjọ́ ìsinmi mọ́.

Tún rántí mi fún èyí, Ọlọ́run mi, o fi àánú un rẹ hàn fún mi gẹ́gẹ́ i títóbi ìfẹ́ ̀ rẹ.

23 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, mo àwọn ọkùnrin Juda wọ́n fẹ́ àwọn obìnrin láti Aṣdodu, Ammoni àti Moabu. 24 Ìdajì àwọn ọmọ wọn ń sọ èdè Aṣdodu tàbí èdè ̀kan lára àwọn ènìyàn mìíràn tókù, wọn mọ a ṣe ń sọ èdè Juda. 25 Mo wọn mo gégùn ún wọn lórí. Mo lu àwọn ènìyàn díẹ̀ nínú wọn mo fa irun orí wọn tu. Mo wọn búra orúkọ Ọlọ́run, wọn , "̀yin yóò fi àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin yín ìyàwó tàbí fún ̀yin tìkára yín. 26 í ha á ṣe àwọn ìgbéyàwó irú èyí ni ọba Solomoni fi ̀ṣẹ̀? Láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ọba kan i tirẹ̀. Ọlọ́run rẹ̀ fẹ́ràn rẹ̀, Ọlọ́run fi jẹ ọba lórí i gbogbo Israẹli, ṣùgbọ́n àwọn obìnrin àjèjì ti sọ ́ sínú òfin ̀ṣẹ̀. 27 Ǹjẹ́ ó ha yẹ àwa tún gbọ́ báyìí ̀yin náà tún ń ṣe àwọn nǹkan ó burú jọjọ wọ̀nyí ń ṣe aláìṣòótọ́ Ọlọ́run wa nípa fífẹ́ àwọn obìnrin àjèjì?"

28 ̀kan lára àwọn ọmọ Joiada, ọmọ Eliaṣibu olórí àlùfáà jẹ́ àna Sanballati ará a Horoni. Mo e jáde kúrò lọ́dọ̀ mi.

29 Rántí wọn, Ọlọ́run mi, nítorí wọ́n ti ba iṣẹ́ àlùfáà jẹ́ pẹ̀májẹ̀iṣẹ́ àlùfáà àti ti àwọn Lefi.

30 Nítorí náà, mo ya àwọn àlùfáà àti àwọn Lefi mímọ́ kúrò nínú gbogbo ohun àjèjì, mo yan iṣẹ́ fún wọn, olúkúlùkù ẹnu iṣẹ́ rẹ̀. 31 Mo tún pèsè fún ọrẹ, igipákó àkókò a yàn àti fún àwọn èso àkọ́so.

Rántí mi fún rere, Ọlọ́run mi.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também