Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 19

1 Èyí ohun Olúwa : "Lọ ra ìkòkò lọ́dọ̀ alámọ̀, dání lára àwọn àgbàgbà ọkùnrin àti wòlíì. 2 o lọ àfonífojì ọmọ Beni-Hinnomu, níwájú ẹnu ibodè Harsiti, níbẹ̀ ni o kéde gbogbo ̀rọ̀ èmi yóò sọ fún . 3 o , Gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa ̀yin ọba àwọn Juda àti ̀yin ará Jerusalẹmu. Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli sọ. Dẹtí mi! Èmi yóò ìparun síbí, etí gbogbo wọn gbọ́ yóò yaya. 4 Nítorí wọ́n ti gbàgbé mi, wọ́n ti sọ ibí di ilé fún òrìṣà àjèjì; wọ́n ti sun ẹbọ nínú rẹ̀ fún òrìṣà àwọn baba wọn tàbí ọba Juda mọ̀ , wọ́n ti fi ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ kún ilẹ̀ yìí. 5 Wọ́n ti kọ́ ibi gíga fún Baali láti sun ọmọkùnrin wọn gẹ́gẹ́ ohun ẹbọ sísun Baalièyí èmi pàṣẹ láti ṣe, èmi sọ, tàbí ru sókè láti inú ọkàn mi. 6 Nítorí náà ṣọ́ra ọjọ́ ń bọ̀ ni Olúwa nígbà àwọn ènìyàn yóò pe ibí Tofeti mọ́ tàbí àfonífojì ọmọ Hinnomu, ṣùgbọ́n àfonífojì Ìpakúpa.

7 " ibí yìí ni èmi yóò ti pa èrò Juda àti Jerusalẹmu run. Èmí yóò wọn ṣubú nípa idà níwájú àwọn ̀wọn, lọ́wọ́ àwọn ó ń ̀wọn. Èmi yóò fi òkú wọn ṣe oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ojú ̀run àti ẹranko ilẹ̀. 8 Èmi yóò sọ ìlú yìí di ahoro àti ohun ̀gàn, gbogbo àwọn ń kọjá yóò bẹ̀wọn yóò máa fòyà nítorí gbogbo ọgbẹ́ rẹ̀. 9 Èmi yóò wọ́n jẹ ẹran-ara ọmọ wọn ọkùnrin àti ẹran-ara ọmọ wọn obìnrin, ẹnìkínní yóò jẹ ẹran-ara ẹnìkejì, nígbà ìdótì àti ìhámọ́ láti ọwọ́ ̀wọn, àti àwọn ó ń ̀wọn.

10 "Nígbà náà ni ìwọ yóò fọ́ ìkòkò náà ojú àwọn ó lọ. 11 o sọ fún wọn , Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun . Èmi a fọ́ orílẹ̀-èdè yìí àti ìlú yìí gẹ́gẹ́ ìkòkò amọ̀ yìí ṣe fọ́ àtúnṣe. Wọn a sin àwọn òkú Tofeti títí fi ààyè mọ́. 12 Èyí ni ohun èmi yóò ṣe ibí yìí àti àwọn ń gbé ibí yìí ni Olúwa . Èmi yóò ìlú yìí dàbí Tofeti. 13 19.13: Ap 7.42.Àwọn ilé ó Jerusalẹmu àti ti ọba ìlú Juda ni a ó sọ di àìmọ́ Tofeti, gbogbo ilé wọ́n ti ń sun tùràrí ni orí òrùlé gbogbo ogun ̀run, a ń ẹbọ mímu ọlọ́run mìíràn.’ "

14 Jeremiah padà láti Tofeti níbi Olúwa rán an láti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ó dúró gbangba tẹmpili Olúwa, ó sọ fún gbogbo ènìyàn , 15 "Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli : Tẹ́sílẹ̀! Èmi yóò ìdààmú mo ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀ ìlú yìí àti ìgbèríko ó i , nítorí ọlọ́rùn líle ni wọ́n, wọn si fẹ́ fetí ̀rọ̀ mi.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também