Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 16

Ọjọ́ àjálù

1 Bákan náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ìwọ gbọdọ̀ ìyàwó, bẹ́̀ ni ìwọ gbọdọ̀ ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin níbí yìí." 3 Nítorí èyí ni ohun Olúwa nípa ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin wọ́n nílẹ̀ yìí, àti ìyá ó wọn àti baba wọn. 4 "Wọn yóò ikú ààrùn, wọn sin wọ́n tàbí ṣọ̀fọ̀ fún wọn. Wọn ó dàbí ìdọ̀lórí ilẹ̀; wọn ó ṣègbé pẹ̀idà àti ìyàn. Òkú wọn yóò di oúnjẹ fún ẹyẹ ojú ̀run àti ẹranko ilẹ̀."

5 Nítorí báyìí ni Olúwa : "ṣe wọ ilé oúnjẹ ìsìnkú , ṣe lọ síbẹ̀ láti káàánú tàbí ṣọ̀fọ̀, nítorí mo ti àlàáfíà, ìfẹ́ àti àánú mi kúrò lórí àwọn ènìyàn wọ̀nyí," ni Olúwa . 6 "Àti ẹni ńlá àti kékeré ni yóò ṣègbé ilẹ̀ yìí, wọn sin wọ́n tàbí ṣọ̀fọ̀ wọn, bẹ́̀ ni ẹni yóò irun orí wọn nítorí wọn. 7 ẹni yóò fi oúnjẹ tu àwọn í ṣọ̀fọ̀ nínú, kódà í ṣe fún baba tàbí fún ìyá, yóò ẹni yóò fi ohun mímu wọ́n nínú.

8 "Ìwọ gbọdọ̀ lọ ilé àjọyọ̀ , ṣe jókòó jẹun tàbí mu ohun mímu. 9 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run àwọn ọmọ Israẹli , ojú yín ọjọ́ yín ni òpin yóò ìró ayọ̀ àti ìdùnnú, àti ohùn ìyàwó àti ọkọ ìyàwó ibí yìí.

10 "Nígbà o sọ nǹkan wọ̀nyí fún àwọn ènìyàn yìí, wọ́n bi ́ , Èéṣe Olúwa ṣe búburú yìí wa? ni àṣìṣe àwa ṣe? Kín ni ̀ṣẹ̀ àwa ṣẹ̀ Olúwa Ọlọ́run wa?11 Nígbà náà ni ìwọ yóò sọ fún wọn , Nítorí àwọn baba yín ti kọ̀ sílẹ̀,’ ni Olúwa , wọ́n tẹ̀àwọn òrìṣà mìíràn wọ́n ń bọ, wọ́n ń sìn, wọ́n kọ̀ sílẹ̀ wọn tẹ̀òfin mi mọ́. 12 Ṣùgbọ́n ̀yin ti ṣe búburú ju ti àwọn baba yín lọ. ó gbogbo yín ṣe ń rìn, olúkúlùkù yín nínú agídí ọkàn búburú rẹ̀, dípò fi gbọ́ tèmi. 13 Èmi yóò gbé yin kúrò ilẹ̀ yìí lọ ilẹ̀ baba yín tàbí ̀yin mọ̀ , níbẹ̀ ni ̀yin yóò ti máa sìn ọlọ́run kéékèèké ̀sán àti òru nítorí èmi yóò fi ojúrere yín.

14 "Nítorí náà, ọjọ́ náà ń bọ̀ ," ni Olúwa , "àwọn ènìyàn sọ , Dájúdájú Olúwa láààyè Olúwa ń bẹ, Ẹni ó Israẹli jáde kúrò Ejibiti.15 Ṣùgbọ́n wọn yóò sọ , Olúwa ṣe nítòótọ́ ó àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ilẹ̀ àríwá àti gbogbo orílẹ̀-èdè ó ti wọn.Bẹ́̀ ni èmi yóò wọn padà ilẹ̀ mo fún àwọn baba ńlá wọn.

16 "Ṣùgbọ́n báyìí, Èmi yóò ránṣẹ́ àwọn apẹja púpọ̀," ni Olúwa . "Wọn ó dẹ wọ́n lẹ́yìn èyí yìí èmi yóò ránṣẹ́ àwọn ọdẹ púpọ̀, wọn yóò dẹ wọ́n lórí gbogbo òkè ńlá àti òkè gíga, àti gbogbo pálapàla àpáta. 17 Ojú mi gbogbo ̀wọn, wọn pamọ́ fún mi bẹ́̀ ni ̀ṣẹ̀ wọn fi ara sin lójú mi. 18 Èmi yóò san ̀san ìwà búburú àti ̀ṣẹ̀ wọn fún wọn ìlọ́po méjì, nítorí wọ́n ti ba ilẹ̀ mi jẹ́ pẹ̀àwọn ère wọn aláìlẹ́mìí, wọ́n fi òkú àti ohun ̀gbin àti ìríra wọn kún ilẹ̀ ìní mi."

19 Olúwa, alágbára àti okun mi,

ẹni ààbò mi ọjọ́ ìpọ́njú,

àwọn orílẹ̀-èdè yóò láti

òpin ayé ,

"Àwọn baba ńlá wa ohun kan ṣe ̀gbin òrìṣà,

ìríra dára fún wọn nínú rẹ̀.

20 Ṣé àwọn ènìyàn Ọlọ́run

fún ara wọn ? Bẹ́̀ ni,

ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí í ṣe Ọlọ́run."

21 "Nítorí náà, Èmi yóò kọ́ wọn

àkókò yìí,

Èmi yóò kọ́ wọn pẹ̀agbára àti títóbi mi.

Nígbà náà ni wọn ó mọ

orúkọ mi

Olúwa.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também