Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 50

Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Babeli

1 50.1–51.64: Isa 13.1–14.23; 47.1-15; Hk 1–2. Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa fi sẹ́nu wòlíì Jeremiah láti sọ fún ará ilẹ̀ Babeli:

2 "sọ ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, kéde,

gbé àsíá sókè, kéde rẹ̀

ṣe ó, ,

A Babeli,

ojú Beli,

a fọ́ Merodaki túútúú,

ojú ti àwọn ère rẹ̀,

a fọ́ àwọn òrìṣà rẹ̀ túútúú.

3 Àwọn ìlú apá àríwá yóò

máa gbóguntì wọ́n.

Gbogbo àwọn ènìyàn àti ẹranko ni yóò

kúrò ìlú yìí.

4 "ọjọ́ wọ̀nyí àti àkókò náà,"

ni Olúwa ,

"Àwọn ọmọ Israẹli yóò jùmọ̀ ,

àwọn, àti àwọn ọmọ Juda,

wọn yóò lọ pẹ̀ẹkún láti ṣàfẹ́

Olúwa Ọlọ́run wọn.

5 Wọn ó máa béèrè ̀Sioni,

ojú wọn yóò síhà ibẹ̀,

, jẹ́ a darapọ̀ mọ́ Olúwa

májẹ̀ayérayé,

a yóò gbàgbé.

6 "Àwọn ènìyàn mi ti jẹ́ àgùntàn ó sọnù,

àwọn olùṣọ́-àgùntàn wọn ti jẹ́ wọn ṣìnà,

wọ́n ti jẹ́ wọn rìn lórí òkè

wọ́n ti lọ láti orí òkè ńlá òkè kékeré,

wọn ti gbàgbé ibùsùn wọn.

7 Gbogbo àwọn ó wọn, ti pa wọ́n jẹ

àwọn ̀wọ́n , Àwa jẹ̀bi

nítorí wọ́n ti ṣẹ̀ Olúwa ibùgbé

òdodo àti ìrètí àwọn baba wọn.

8 "Jáde kúrò Babeli,

fi ilẹ̀ àwọn ará Kaldea sílẹ̀,

jẹ́ òbúkọ níwájú agbo ẹran.

9 Nítorí èmi yóò ru,

bẹ́̀ ni èmi yóò gbé sókè Babeli àwọn orílẹ̀-èdè

ńlá láti ilẹ̀ àríwá. Wọn yóò gba àyà wọn lẹ́gbẹ́ rẹ̀;

láti àríwá , à ó . Ọfà wọn yóò

dàbí ọfà àwọn akọni akíkanjú wọn í lọ́wọ́ òfo.

10 A ó dààmú Babeli,

gbogbo àwọn dààmú rẹ yóò ìfẹ́ wọn ṣẹ,"

ni Olúwa .

11 "Nítorí inú yín dùn nítorí ̀yìn yọ̀,

̀yìn olè ó ìní mi, nítorí ̀yìn

fi ayọ̀ ẹgbọrọ abo màlúù koríko tútù,

ń yan akọ ẹṣin.

12 Ojú yóò ti ìyá rẹ, ẹni ó

yóò gba ìtìjú.

Òun ni yóò jẹ́ kékeré nínú àwọn orílẹ̀-èdè,

ilẹ̀ aṣálẹ̀ àti aginjù lọ́ràá.

13 Nítorí ìbínú Olúwa, yóò olùgbé;

ẹnikẹ́ni gbé inú rẹ̀.

Gbogbo àwọn ó kọjá ni Babeli yóò

fi ṣe yẹ̀yẹ́ nítorí ọgbẹ́ rẹ̀.

14 "Dúró ààyè rẹ ìwọ Babeli

àti gbogbo ̀yin n ta ọfà náà.

ta ọfà náà i, nítorí ó ti ṣẹ̀ Olúwa.

15 Kígbe mọ́ ọn gbogbo ̀!

Ó tẹríba, òpó rẹ̀ yẹ̀,

níwọ̀n ìgbà ó ti jẹ́ èyí ni ìgbẹ̀san Olúwa,

gbẹ̀san lára rẹ̀.

Ṣe i gẹ́gẹ́ ó ti ṣe àwọn ẹlòmíràn.

16 afúnrúgbìn kúrò Babeli,

àti ẹni ń di dòjé igà ìkórè!

Nítorí idà àwọn aninilára

jẹ́ oníkálùkù padà ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀,

oníkálùkù padà ilẹ̀ rẹ̀.

17 "Israẹli jẹ́ àgùntàn ó ṣìnà kiri,

kìnnìún ti e lọ.

Níṣàájú ọba Asiria pa á jẹ,

àti níkẹyìn yìí Nebukadnessari ọba Babeli

fa egungun rẹ̀ ya."

18 Nítorí náà, èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Alágbára, Ọlọ́run Israẹli ,

"Ǹ ó fi ìyà jẹ ọba Babeli àti ilẹ̀ rẹ̀

gẹ́gẹ́ mo ti ṣe fìyà jẹ ọba, Asiria.

19 Ṣùgbọ́n, èmi yóò Israẹli

padà pápá oko tútù rẹ̀

òun yóò máa bọ́ ara rẹ̀ lórí Karmeli àti Baṣani,

a ó tẹ́ ọkàn rẹ̀ lọ́rùn òkè

Efraimu àti Gileadi.

20 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,"

ni Olúwa ,

"À ó àìṣedéédéé ̀ṣẹ̀ Israẹli,

ṣùgbọ́n a ki yóò ohun;

àti ̀ṣẹ̀ Juda ni a ki yóò mọ kankan

nítorí èmi yóò dáríjì àwọn ó ṣẹ́mo .

21 "Kọlu ilẹ̀ Merataimu àti àwọn

ó ń gbé Pekodi.

Lépa rẹ pa, o parun pátápátá,"

ni Olúwa ,

"Ṣe gbogbo ohun mo pàṣẹ fún .

22 Ariwo ogun ilẹ̀ náà

ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ìparun ńlá.

23 Báwo ni ó ṣe fọ́, ó pín yẹ́lẹyẹ̀lẹ ,

lọ́wọ́ òòlù gbogbo ayé!

Báwo Babeli ti di ahoro

ni àárín àwọn orílẹ̀-èdè.

24 Mo dẹ pàkúté sílẹ̀

fún ìwọ Babeli,

o mọ ohun ó ń ṣẹlẹ̀,

o ti sínú rẹ̀. A nítorí o tako Olúwa.

25 Olúwa ti àwọn ohun èlò ìjà rẹ̀ jáde,

nítorí Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun

ti ṣiṣẹ́ ilẹ̀ Babeli.

26 sórí rẹ̀ láti òpin gbogbo,

ilé ìṣúra rẹ̀ sílẹ̀,

o jọ òkìtì ọkà,

á sọ́tọ̀ fún ìparun,

ṣe yòókù sílẹ̀ fún un.

27 Pa gbogbo àwọn akọ màlúù rẹ,

jẹ́ a wọn lọ ibi a ó ti pa wọ́n!

Ègbé fún wọn! Nítorí ọjọ́ wọn ,

àkókò ìbẹ̀wọn.

28 Gbọ́ ohùn àwọn ó sálọ, ó sálà láti Babeli ,

sọ Sioni,

Olúwa Ọlọ́run wa ti gbẹ̀san,

̀san fún tẹmpili rẹ̀.

29 "Pe ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àní gbogbo tafàtafà, sórí Babeli,

ì yíkákiri, ma jẹ́ ki ẹnikẹ́ni sálà.

Sán fún un gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀

gẹ́gẹ́ bi gbogbo èyí ó ti ṣe,

ṣe bẹ́̀ i, nítorí ó ti gbéraga

Olúwa, Ẹni Mímọ́ Israẹli.

30 Nítorí náà, àwọn ọmọkùnrin rẹ̀

yóò ṣubú ìgboro, a ó pa àwọn

ológun lẹ́nu mọ́,"

Olúwa .

31 "ó, èmi yóò dojú kọ ́ ìwọ agbéraga,"

ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ,

"nítorí ọjọ́ rẹ ti ,

àkókò èmi ó bẹ̀ .

32 Onígbèéraga yóò kọsẹ̀, yóò ṣubú,

yóò ṣí ẹni yóò gbé dìde.

Èmi yóò tan iná ìlú náà,

èyí yóò jo run."

33 Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ:

"A pọ́n àwọn ènìyàn Israẹli

lójú àti àwọn ènìyàn Juda pẹ̀.

Gbogbo àwọn ó wọn

nígbèkùn wọn ṣinṣin

wọn jẹ́ ó àsálà.

34 Síbẹ̀, Olùràpadà wọn, Alágbára,

Olúwa Ọlọ́run Alágbára ni orúkọ rẹ̀.

Yóò gbe ìjà wọn ,

ó ba à wọn sinmi ilẹ̀ náà;

ṣùgbọ́n ìsinmi fún àwọn ó ń gbé Babeli.

35 "Idà lórí àwọn Babeli!"

ni Olúwa ,

"lòdì àwọn ń gbé Babeli,

àwọn aláṣẹ àti àwọn amòye ọkùnrin.

36 Idà lórí àwọn wòlíì èké

wọn yóò di òmùgọ̀! Idà lórí àwọn jagunjagun,

wọn yóò kún fún ̀.

37 Idà lórí àwọn kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀

àti àwọn àjèjì nínú ẹgbẹ́ rẹ̀.

Wọn yóò di obìnrin.

Idà lórí àwọn ohun ìṣúra rẹ̀!

38 Ilẹ̀ gbígbẹ lórí omi rẹ̀; yóò gbẹ.

Nítorí ó jẹ́ ilẹ̀ àwọn ère,

àwọn ère yóò ya òmùgọ̀ pẹ̀̀.

39 "Nítorí náà àwọn ẹranko ijù

pẹ̀̀wàwà ni yóò máa gbé ibẹ̀,

abo ògòǹgò yóò máa gbé inú rẹ̀,

a yóò gbé inú rẹ̀ mọ́, láéláé,

bẹ́̀ ni a yóò ṣàtìpó nínú rẹ̀ láti ìrandíran.

40 Gẹ́gẹ́ Olúwa ti gba ìjọba Sodomu àti Gomorra

pẹ̀àwọn ìlú agbègbè wọn,"

ni Olúwa ,

"torí náà ẹnikẹ́ni yóò gbé ibẹ̀;

ènìyàn ki yóò gbé nínú .

41 "ó! ̀wọ́ ọmọ-ogun láti ìhà àríwá;

orílẹ̀-èdè ńlá àti àwọn ọba púpọ̀ ni à ń

gbé dìde láti òpin ilẹ̀ ayé.

42 Wọ́n di ìhámọ́ra ̀kọ̀ àti ọrun,

wọ́n burú wọn àánú.

Wọ́n n i rírú omi wọ́n ti ṣe ń gun ẹṣin wọn lọ.

Wọ́n àkójọpọ̀ ogun láti kọlù ́, ìwọ ọmọbìnrin Babeli.

43 Ọba Babeli ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn,

ọwọ́ wọn rọ,

ìrora wọn obìnrin ó ń rọbí.

44 i kìnnìún ni òun ó gòkè láti igbó Jordani

orí ilẹ̀ ọlọ́ràá,

Èmi ó Babeli kúrò ilẹ̀ rẹ̀ kíákíá.

Ta ni àyànfẹ́ náà èmi ó yàn sórí rẹ̀?

Ta dàbí mi, ta ni ó mi ṣe ẹlẹ́rìí?

Ta ni olùṣọ́-àgùntàn náà yóò le dúró níwájú mi?"

45 Nítorí náà, gbọ́ ohun

Olúwa sọ nípa Babeli,

ẹni ó gbìmọ̀ lòdì Babeli:

n ó pa agbo ẹran wọn run.

46 ohùn igbe ńlá ;

a Babeli, ilẹ̀ ayé yóò tìtì,

a gbọ́ igbe náà

láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também