Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 5

̀kan o jẹ́ olóòtítọ́

1 "Lọ sókè àti sódò àwọn òpópó Jerusalẹmu,

yíká, o mọ̀,

o kiri.

o le è ẹnìkan,

ó jẹ́ olóòtítọ́ àti olódodo,

n ó dáríjì ìlú yìí.

2 wọ́n tilẹ̀ , Olúwa ti ń bẹ,

síbẹ̀ wọ́n búra èké."

3 Olúwa, ojú rẹ ha lára òtítọ́?

Ìwọ wọ́n, dùn wọ́n;

ìwọ wọn , wọ́n kọ̀ láti yípadà.

Wọ́n ojú wọn le ju òkúta lọ,

wọ́n kọ̀ láti yípadà.

4 Èmi , "Tálákà ni àwọn yìí;

wọn jẹ́ aṣiwèrè,

nítorí wọn mọ ̀Olúwa,

àti ohun Ọlọ́run wọn ń fẹ́.

5 Nítorí náà, èmi yóò tọ àwọn adarí lọ,

n ó wọn sọ̀rọ̀;

ó dájú wọ́n mọ ̀Olúwa

àti ohun Ọlọ́run wọn ń fẹ́."

Ṣùgbọ́n pẹ̀ìfìmọ̀ṣọ̀kan, wọ́n ti ba àjàgà jẹ́,

wọ́n ti ìdè.

6 Nítorí náà, kìnnìún láti inú igbó yóò kọlù wọ́n,

ìkookò aginjù yóò pa wọ́n run,

ẹkùn yóò máa ṣe ibùba ̀ìlú yín

ẹnikẹ́ni ó jáde ni yóò fàya pẹ́rẹpẹ̀rẹ,

nítorí àìgbọ́ràn yín pọ,

ìpadàsẹ́yìn wọn pọ̀.

7 "ni ṣe èmi ó ṣe dáríjì ́?

Àwọn ọmọ rẹ ti kọ̀ sílẹ̀

àti wọ́n ti fi ọlọ́run í ṣe Ọlọ́run búra.

Mo pèsè fún gbogbo àìní wọn,

síbẹ̀ wọ́n tún ń ṣe panṣágà

wọ́n kórajọ ilé àwọn alágbèrè.

8 Wọ́n jẹ́ akọ ẹṣin a bọ́ ,

ó lágbára, wọ́n ń sọkún aya arákùnrin wọn.

9 Èmi yóò ha ṣe ìbẹ̀nítorí nǹkan wọ̀nyí?"

ni Olúwa .

"Èmi yóò gba ̀san fúnra mi

lára irú orílẹ̀-èdè èyí ?

10 "Lọ ọgbà àjàrà rẹ̀, pa wọ́n run,

ṣe pa wọ́n run pátápátá.

Ya ̀ka rẹ̀ kúrò,

nítorí àwọn ènìyàn wọ̀nyí í ṣe ti Olúwa.

11 Ilé Israẹli àti ilé Juda

ti jẹ́ aláìṣòdodo mi,"

ni Olúwa .

12 Wọ́n ti pa irọ́ mọ́ Olúwa;

wọ́n , "Òun yóò ṣe ohun kan!

Ibi kan yóò tọ̀ ;

àwa yóò idà tàbí ìyàn.

13 Àwọn wòlíì dàbí afẹ́fẹ́,

̀rọ̀ nínú wọn.

Nítorí náà, jẹ́ ohun wọ́n sọ ṣẹlẹ̀ wọn."

14 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára :

"Nítorí àwọn ènìyàn ti sọ àwọn ̀rọ̀ wọ̀nyí;

Èmi yóò sọ ̀rọ̀ mi lẹ́nu wọn di iná,

àti àwọn ènìyàn wọ̀nyí di igi yóò jórun.

15 Háà, ̀yin ilé Israẹli," ni Olúwa ,

"Èmi yóò orílẹ̀-èdè láti ̀jíjìn dìde i yín

Orílẹ̀-èdè àtijọ́ àti alágbára

àwọn ènìyàn ìwọ mọ èdè rẹ̀,

̀rọ̀ rẹ̀ .

16 Apó-ọfà rẹ dàbí isà òkú a ṣí

gbogbo wọn jẹ́ akọni ènìyàn.

17 Wọn yóò jẹ ìkórè rẹ àti oúnjẹ rẹ,

àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti obìnrin,

wọn yóò jẹ agbo àti ẹran rẹ,

wọn yóò jẹ àjàrà àti igi ̀pọ̀tọ́ rẹ.

Pẹ̀idà ni wọn ó run

ìlú ìwọ gbẹ́kẹ̀.

18 "ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì," ni Olúwa , "Èmi yóò pa yín run pátápátá. 19 Àti , nígbà àwọn ènìyàn béèrè , ni ìdí rẹ̀ Olúwa Ọlọ́run wa fi ṣe gbogbo èyí wa?Ìwọ yóò sọ fún wọn , ̀yin ti kọ̀ sílẹ̀, ń sin ọlọ́run àjèjì ilẹ̀ yín. Nísinsin yìí, ̀yin yóò máa sin àjèjì ilẹ̀ í ṣe tiyín.

20 "Kéde èyí fún ilé Jakọbu,

polongo rẹ̀ Juda.

21 5.21: Isa 6.9-10; Mt 13.10-15; Mk 8.17-18. Gbọ́ èyí, ̀yin aṣiwèrè àti aláìlọ́gbọ́n ènìyàn,

ó lójú ti fi ríran

ó létí ti fi gbọ́rọ̀.

22 ha yẹ bẹ̀mi?"

ni Olúwa .

"ha yẹ ̀yin ó wárìrì níwájú mi ?

Mo fi yanrìn pààlà òkun,

èyí le è rékọjá rẹ̀ láéláé.

Ìjì , le è borí rẹ̀;

wọ́n le è , wọn le è rékọjá rẹ̀.

23 Ṣùgbọ́n, àwọn ènìyàn wọ̀nyí ọkàn líle àti ọkàn ̀tẹ̀,

wọ́n ti yípadà, wọ́n ti lọ.

24 Wọn sọ fún ara wọn ,

jẹ́ a bẹ̀Olúwa Ọlọ́run wa,

ẹni ó fún wa òjò àkọ́rọ̀ àti àrọ̀kúrò òjò ìgbà rẹ̀,

ó fi lọ́kàn balẹ̀ nípa ìkórè ̀sẹ̀ déédé.

25 Àìṣedéédéé yín gbogbo nǹkan wọ̀nyí kúrò,

̀ṣẹ̀ yín a fi nǹkan rere yín.

26 "Láàrín ènìyàn mi ni ìkà ènìyàn

ó ibùba ẹni ó ń dẹ ẹyẹ,

àti àwọn ó ń dẹ pàkúté láti ènìyàn.

27 àgò ó kún fún ẹyẹ,

ilé wọn kún fún ̀tàn;

wọ́n ti di ọlọ́àti alágbára,

28 wọ́n sanra wọ́n ń dán.

Ìwà búburú wọn lópin;

wọn bẹ̀bẹ̀ fún ẹjọ́ àwọn aláìní baba láti borí rẹ̀.

Wọn fún ̀tọ́ àwọn tálákà.

29 Èmi yóò ha fi ìyà jẹ wọ́n fún èyí ?"

ni Olúwa .

"Èmi yóò gbẹ̀san ara mi

lára orílẹ̀-èdè èyí ?

30 "Nǹkan ìbànújẹ́ àti ohun ìtara

ti ṣẹlẹ̀ ilẹ̀ náà.

31 Àwọn wòlíì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké,

àwọn àlùfáà ń ṣe àkóso pẹ̀àṣẹ ara wọn,

àwọn ènìyàn mi ìfẹ́ èyí,

ni ̀yin yóò ṣe òpin?

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também