Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 49

Àṣọtẹ́lẹ̀ nípa Ammoni

1 49.1-6: El 21.28-32; 25.1-7; Am 1.13-15; Sf 2.8-11. Nípa Ammoni.

Báyìí ni Olúwa ,

"Israẹli ha ọmọkùnrin?

Israẹli ha àrólé ?

Nítorí ni Malkomu ṣe jogún Gadi?

àwọn ènìyàn rẹ̀ ń gbé ìlú rẹ̀?

2 Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà ń bọ̀,"

ni Olúwa ;

"nígbà èmi yóò a gbọ́ ìdágìrì ogun

Rabba Ammoni;

yóò di òkìtì ahoro,

gbogbo ìlú ó i ni a ó níná.

Nígbà náà ni Israẹli yóò wọn,

àwọn ó ti e jáde,"

ni Olúwa .

3 "Hu, ìwọ Heṣboni, nítorí Ai rún!

Kígbe ̀yin olùgbé Rabba!

wọ aṣọ ̀fọ̀ ṣọ̀fọ̀.

sáré sókè sódò nínú ọgbà,

nítorí Malkomu yóò lọ ìgbèkùn,

pẹ̀àwọn àlùfáà àti ìjòyè rẹ̀.

4 Èéṣe ìwọ fi ń ṣògo nínú àfonífojì rẹ,

ṣògo nínú àfonífojì rẹ fún èso?

̀yin ọmọbìnrin Ammoni aláìṣòótọ́,

gbẹ́kẹ̀ọrọ̀ yín, ,

Ta ni yóò lójú?

5 Èmi yóò mu ̀lórí rẹ

láti ̀dọ̀ gbogbo àwọn ,"

ni Olúwa, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

6 "Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

Gbogbo yín ni ó jáde, ṣí ẹnìkan

yóò ìkólọ Ammoni padà,"

ni Olúwa .

Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Edomu

7 49.7-22: Isa 34; 63.1-6; El 25.12-14; 35; Am 1.11-12; Ml 1.2-5. Nípa Edomu.

Èyí ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun :

"Ṣe ha ọgbọ́n mọ́ ni Temani?

Ṣé a ti ìmọ̀ràn kúrò ̀dọ̀ olóyè?

Ṣé ọgbọ́n wọn ti bàjẹ́ ?

8 Yípadà o sálọ, pamọ́ sínú ihò,

ìwọ ó ń gbé Dedani,

nítorí èmi yóò ibi sórí Esau,

àkókò èmi ó bẹ̀ ́ .

9 àwọn ń ṣa èso tọ̀ ́ ;

ǹjẹ́ wọn fi èso díẹ̀ sílẹ̀?

olè òru; ǹjẹ́ wọn

gbogbo ohun wọ́n fẹ́?

10 Ṣùgbọ́n èmi yóò tu Esau ìhòhò,

èmi ti fi ibi ìkọ̀kọ̀ rẹ̀ hàn,

nítorí o máa ba à fi ara rẹ pamọ́.

Àwọn ọmọ rẹ, ẹbí rẹ àti

àwọn ará ilé rẹ yóò parun.

Wọn mọ́.

11 Fi àwọn ọmọ aláìní baba sílẹ̀

èmi yóò dáàbò bo ̀wọn.

Àwọn opó rẹ gan an gbẹ́kẹ̀mi."

12 Èyí ni ohun Olúwa ẹnikẹ́ni yẹ ó mu ago náà un, ìwọ yóò fi lọ láìjìyà? Ìwọ lọ láìjìyà; ṣùgbọ́n ìwọ yóò un. 13 Èmi fi ara mi búra ni Olúwa , , "Bosra yóò ba ayé ara rẹ̀ jẹ́. Yóò di ẹni ̀gàn, ẹni èpè àti ẹni ègún, àti gbogbo ìlú rẹ̀ yóò di ìbàjẹ́ títí láé."

14 gbígbọ́, èmi ti gbọ́ ìró kan láti ̀dọ̀ Olúwa,

a rán ikọ̀ kan orílẹ̀-èdè ,

ara yín jọ, sórí rẹ̀, dìde láti jagun.

15 "báyìí, èmi yóò sọ ́ di

kékeré láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo;

ẹni ̀gàn láàrín àwọn ènìyàn.

16 Ìpayà ìwọ ti sínú

ìgbéraga ọkàn rẹ ti tàn ́ jẹ;

ìwọ ń gbé pàlàpálá àpáta,

o jókòó lórí ìtẹ́ gíga

síbẹ̀ o kọ́ ìtẹ́ rẹ ga gẹ́gẹ́ ẹyẹ idì;

láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti sọ̀kalẹ̀ ,"

ni Olúwa .

17 "Edomu yóò di ahoro

gbogbo àwọn ń kọjá yóò jáyà, wọn ó

fi rẹ́rìn-ín ẹlẹ́nítorí gbogbo ìpalára rẹ.

18 Gẹ́gẹ́ wọ́n ṣe gba Sodomu

àti Gomorra pẹ̀àwọn ìlú

ó àyíká rẹ,"

Olúwa .

"Bẹ́̀ ni, ẹnikẹ́ni yóò gbé níbẹ̀;

ènìyàn yóò tẹ̀síbẹ̀ mọ́.

19 "i kìnnìún ni òun ó gòkè láti igbó Jordani orí ilẹ̀ ọlọ́ràá,

Èmi ó Edomu kúrò ilẹ̀ rẹ̀ kíákíá.

Ta ni àyànfẹ́ náà èmi ó yàn sórí rẹ̀?

Ta dàbí mi, ta ni ó mi ṣe ẹlẹ́rìí?

Ta ni olùṣọ́-àgùntàn náà yóò le dúró níwájú mi?"

20 Nítorí náà, gbọ́ ohun

Olúwa fún Edomu,

ohun ó pàtàkì fún àwọn ń gbé Temani.

Àwọn ̀dọ́ àgbò ni à ó jáde;

pápá oko wọn ni yóò run nítorí wọn.

21 Ilẹ̀ yóò tìtì nípa ariwo ìṣubú wọn,

a ó gbọ́ igbe wọn

Òkun pupa.

22 ó! Ẹyẹ idì yóò gòkè wálẹ̀,

yóò tẹ ìyẹ́ rẹ̀ lórí Bosra.

ọjọ́ náà ọkàn àwọn ajagun

Edomu yóò dàbí ọkàn obìnrin ń rọbí.

Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Damasku

23 Nípa Damasku.

"Inú Hamati àti Arpadi bàjẹ́ nítorí wọ́n gbọ́ ìròyìn búburú, ìjayà wọn,

wọ́n dààmú omi Òkun.

24 Damasku di aláìlera,

ó pẹ̀yìndà láti sálọ,

ìwárìrì a;

ìbẹ̀àti ìrora dìímú,

ìrora ti obìnrin ó ipò ìrọbí.

25 ìlú olókìkí di ohun ìkọ̀sílẹ̀;

ìlú mo dunnú .

26 Lóòtítọ́, àwọn ̀dọ́mọkùnrin rẹ yóò ṣubú lójú pópó,

gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ yóò pa ẹnu mọ́ ọjọ́ náà,"

Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

27 "Èmi yóò fi iná odi Damasku,

yóò gbọ̀ngàn Beni-Hadadi run."

̀rọ̀ nípa Kedari àti Hasori

28 Nípa ìlú Kedari àti ìjọba Hasori èyí ti Nebukadnessari ọba Babeli dojú ìjà kọ,

èyí ni ohun Olúwa sọ,

"Dìde o dojú ìjà kọ ìlú Kedari,

o pa àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn run.

29 49.29: Jr 6.25; 20.3,10; 46.5; Sm 31.13. Àgọ́ wọn àti agbo àgùntàn wọn ni wọn ó lọ;

àgọ́ wọn yóò di ìṣínípò padà

pẹ̀gbogbo ẹrù àti ìbákasẹ wọn.

Àwọn ènìyàn yóò sórí wọ́n ,

̀káàkiri!

30 "Sálọ kíákíá!

Fi ara pamọ́ ibi jíjìn, ̀yin olùgbé Hasori,"

ni Olúwa .

"Nebukadnessari ọba Babeli ti dojú ìjà kọ ́.

31 "Dìde o dojú ìjà kọ orílẹ̀-èdè ó nínú ìrọ̀rùn,

èyí ó gbé àìléwu,"

Olúwa .

"Orílẹ̀-èdè odi tàbí irin,

àwọn ènìyàn rẹ̀ ń dágbé.

32 Àwọn ìbákasẹ á di ẹrù

àti àwọn ẹran ̀sìn, wọ́n á di ìkógun.

Èmi yóò àwọn ó òkèèrè inú afẹ́fẹ́.

Èmi yóò ibi àyíká gbogbo,"

báyìí Olúwa .

33 "Hasori yóò di ibi ìdọdẹ àwọn akátá,

ibi ìkọ̀sílẹ̀ ayérayé,

ẹni yóò gbé ibẹ̀."

Àṣọtẹ́lẹ̀ nípa Elamu

34 Èyí ̀rọ̀ Olúwa èyí ó tọ Jeremiah wòlíì nípa Elamu ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekiah ọba Juda.

35 Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ:

"ó, èmi yóò fọ́ ìtẹ̀gùn Elamu,

ẹni wọ́n sinmi nípa agbára.

36 Èmi yóò afẹ́fẹ́ orígun mẹ́rẹ̀̀rin

àgbáyé lòdì Elamu.

Èmi yóò wọn ìpín afẹ́fẹ́ mẹ́rin àti ,

orílẹ̀-èdè

ilẹ̀ àjèjì Elamu lọ.

37 Èmi yóò kẹ́gàn Elamu níwájú àwọn ̀wọn,

àti níwájú àwọn wọ́n ń ̀wọn,

Èmi yóò ibi orí wọn,

àní, ìbínú gbígbóná mi,"

bẹ́̀ ni Olúwa .

"Èmi yóò wọn pẹ̀idà, di ìgbà èmi yóò rẹ́yìn wọn.

38 Èmi yóò gbé ìtẹ́ mi kalẹ̀ Elamu,

èmí yóò pa ọba wọn àti ìjòyè wọn run,"

báyìí ni Olúwa .

39 "Síbẹ̀, èmi yóò ìkólọ

Elamu padà láìpẹ́ ọjọ́,"

báyìí ni Olúwa .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também