Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 22

Ìdájọ́ fún àwọn ọba búburú

1 Báyìí ni Olúwa , "Sọ̀kalẹ̀ lọ ààfin ọba Juda, o sọ ̀rọ̀ yìí níbẹ̀: 2 Gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa ìwọ ọba Juda, ó jókòó ìtẹ́ Dafidi, ìwọ, àwọn ènìyàn rẹ àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ, ó wọlé láti ẹnu ibodè wọ̀nyí. 3 Báyìí ni Olúwa : Ṣé ohun ó jẹ́ òtítọ́ ó yẹ, o gba ẹni a fi ̀tọ́ rẹ̀ ú kúrò lọ́wọ́ aninilára. ó ṣe fi agbára àti ìkà àlejò, aláìní baba, tàbí opó, ìwọ gbọdọ̀ ta ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ níbí yìí. 4 Nítorí ̀yin tẹ̀àṣẹ wọ̀nyí, nígbà náà ni àwọn ọba ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi yóò gba inú ààfin láti ẹnu-ọ̀, wọn yóò gun kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin, àwọn àti ìránṣẹ́ wọn àti àwọn ènìyàn wọn. 5 Ṣùgbọ́n ̀yin tẹ̀àṣẹ wọ̀nyí, mo búra fúnra mi ààfin yìí yóò di ìparun ni Olúwa .’ "

6 Nítorí báyìí ni Olúwa , nípa ààfin ọba Juda,

"ó tilẹ̀ jẹ́ ìwọ dàbí Gileadi mi,

gẹ́gẹ́ góńgó òkè Lebanoni,

dájúdájú Èmi yóò sọ ́ di aṣálẹ̀,

àní gẹ́gẹ́ ìlú a gbé inú wọn.

7 Èmi ó ya àwọn apanirun sọ́tọ̀ fún ,

olúkúlùkù ọkùnrin pẹ̀ohun ìjà rẹ̀,

wọn yóò àṣàyàn igi kedari rẹ lulẹ̀,

wọn ó wọn sínú iná.

8 "Àwọn ènìyàn láti ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò rékọjá lẹ́bàá ìlú yìí wọn yóò máa bi ara wọn léèrè , Èéṣe Olúwa ṣe irú èyí ìlú ńlá yìí?9 Ìdáhùn wọn yóò jẹ́: Nítorí wọ́n ti kọ májẹ̀Olúwa Ọlọ́run wọn sílẹ̀, wọn ti ń fi orí balẹ̀ fún ọlọ́run mìíràn, wọ́n sìn wọ́n.’ "

10 Nítorí náà ṣe sọkún nítorí ọba ó ti tàbí ṣọ̀fọ̀ fún àdánù rẹ̀,

ṣùgbọ́n sọkún kíkorò fún ẹni a kúrò nílùú

nítorí yóò padà mọ́

tàbí fi ojú ilẹ̀ a ti i.

11 Nítorí báyìí ni Olúwa , nípa Ṣallumu ọmọ Josiah ọba Juda ó jẹ ọba lẹ́yìn baba rẹ̀, ṣùgbọ́n ó jáde kúrò níhìn-ín: "Òun yóò padà mọ́. 12 Yóò ni ibi a u ìgbèkùn lọ, yóò ilẹ̀ yìí mọ́."

13 "Ègbé ni fún ẹni a kọ́ ààfin rẹ̀ lọ́àìṣòdodo,

àti àwọn yàrá òkè rẹ̀ lọ́àìtọ́

ó àwọn ará ìlú rẹ ṣiṣẹ́ lásán

láìsan owó iṣẹ́ wọn fún wọn.

14 Ó , Èmi ó kọ́ ààfin ńlá fún ara mi

àwọn yàrá òkè ó fẹ̀,

ojú fèrèsé rẹ̀ yóò tóbi.

A ó fi igi kedari ó,

a ó fi ohun aláwọ̀ pupa ṣe é ̀ṣọ́.

15 "Ìwọ ó ha jẹ ọba

ìwọ ó ̀pọ̀lọpọ̀ igi kedari?

Baba rẹ ha ohun jíjẹ àti mímu?

Ó ṣe ohun ó tọ́ àti òdodo,

nítorí náà ó dára fún un.

16 Ó gbèjà òtòṣì àti aláìní,

ohun gbogbo dára fún un.

a ti mọ̀ kọ́ ni èyí?"

ni Olúwa .

17 "Ṣùgbọ́n ojú rẹ àti ọkàn rẹ

lára èrè àìṣòótọ́

láti ta ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀

ìnilára àti ìlọ́nilọ́wọ́gbà."

18 Nítorí náà báyìí ni Olúwa , nípa Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda:

"Wọn yóò ṣọ̀fọ̀ fún un:

, Ó ṣe, arákùnrin mi! Ó ṣe, arábìnrin mi!

Wọn yóò ṣọ̀fọ̀ fún un:

, Ó ṣe, olúwa tàbí ó ṣe ọlọ́!

19 A ó sin òkú rẹ̀ i kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́

a wọ́ sọnù láti ẹnu ibodè

Jerusalẹmu."

20 "Gòkè lọ Lebanoni, kígbe síta,

a gbọ́ ohùn rẹ Baṣani,

o kígbe sókè láti Abarimu,

nítorí a ti ṣẹ́ gbogbo olùfẹ́ rẹ túútúú.

21 Èmi ti kìlọ̀ fún nígbà o séwu,

ṣùgbọ́n o sọ , Èmi yóò fetísílẹ̀!’

Èyí ni iṣẹ́ rẹ láti ìgbà èwe rẹ,

ìwọ fìgbà kan gba ohùn mi gbọ́.

22 ̀fúùfù yóò gbogbo àwọn olùṣọ́-àgùntàn rẹ̀ lọ,

gbogbo àwọn olùfẹ́ rẹ yóò lọ ìgbèkùn,

nígbà náà ni a ó kẹ́gàn rẹ, ojú yóò ́

nítorí gbogbo ìwà búburú rẹ.

23 Ìwọ ń gbé Lebanoni,

ó tẹ́ ìtẹ́ orí igi kedari,

ìwọ yóò ti kérora pẹ́ , nígbà ìrora ,

ìrora i ti obìnrin ń rọbí!

24 "Dájúdájú èmi ti láààyè," ni Olúwa , "Koniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda tilẹ̀ jẹ́ òrùka èdìdì lọ́wọ́ ̀tún mi, síbẹ̀ èmi ó ́ tu kúrò níbẹ̀. 25 Èmi ó ́ ọwọ́ àwọn ó ń ̀rẹ, àwọn ìwọ bẹ̀, àní ọwọ́ Nebukadnessari, ọba Babeli àti ọwọ́ àwọn ará Babeli. 26 Èmi ó fi ìwọ àti ìyá ó sọ̀ilẹ̀ mìíràn, níbi a ẹnikẹ́ni nínú yín . Níbẹ̀ ni ̀yin méjèèjì yóò . 27 ̀yin yóò padà ilẹ̀ ̀yin fẹ́ mọ́ láéláé."

28 Ǹjẹ́ Jehoiakini ẹni ̀gàn yàtọ̀ ìkòkò òfìfo,

ohun èlò ẹnìkan fẹ́?

Èéṣe a fi òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ sókè

ilẹ̀ wọn mọ̀.

29 Ìwọ ilẹ̀, ilẹ̀, ilẹ̀,

gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa!

30 Báyìí ni Olúwa :

"Kọ àkọsílẹ̀ ọkùnrin yìí sínú ìwé gẹ́gẹ́ aláìlọ́mọ,

ẹni yóò ṣe rere ọjọ́ ayé rẹ̀;

nítorí ̀kan nínú irú-ọmọ rẹ̀ yóò ṣe rere,

èyíkéyìí wọn yóò jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi

tàbí jẹ ọba Juda mọ́."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também