Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 44

Àjálù nítorí ṣinṣin òrìṣà

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah nípa àwọn Júù ń gbé ìsàlẹ̀ Ejibiti Migdoli, Tafanesi àti Memfisi àti apá òkè Ejibiti: 2 "Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli : Wo ibi mo Jerusalẹmu àti gbogbo ìlú Juda. Lónìí, wọ́n ìyapa àti ìparun. 3 Nítorí ibi wọ́n ti ṣe. Wọ́n mi bínú nípa tùràrí fínfín àti nípa bíbọ àwọn òrìṣà, yálà èyí ìwọ tàbí àwọn baba rẹ mọ̀. 4 ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà mo rán wòlíì mi, èyí ó báyìí , ṣe àwọn ohun ìríra yìí èmi kórìíra.5 Ṣùgbọ́n wọn fetísílẹ̀ láti fi ọkàn si. Wọn yípadà kúrò nínú búburú wọn tàbí dáwọ́ ẹbọ sísun àwọn òrìṣà dúró. 6 Fún ìdí èyí, ìbínú gbígbóná mi ni èmi yóò yọ àwọn ìlú Juda àti òpópó Jerusalẹmu àti sísọ wọ́n di ìparun ó ṣe lónìí yìí.

7 "Báyìí tún ni Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun Israẹli , fi ń mu ibi ńlá yìí orí ara yín nípa yíyapa kúrò lára Juda ọkùnrin àti obìnrin, ọmọdé àti èwe, ku ̀kankan? 8 Èéṣe fi mi bínú pẹ̀ohun ọwọ́ yín ṣe pẹ̀ẹbọ sísun àwọn òrìṣà Ejibiti, níbi láti máa gbé? ̀ ò pa ara yín run, ̀ ó sọ ara yín di ẹni ìfiré àti ̀gàn láàrín àwọn orílẹ̀-èdè ayé gbogbo. 9 Ṣé ̀yin ti gbàgbé ibi àwọn baba ńlá yín àti àwọn ọba; àwọn ayaba Juda, àti àwọn ibi ti ṣe àti àwọn ìyàwó yín ilẹ̀ Juda àti òpópó Jerusalẹmu? 10 Láti ìgbà náà àkókò yìí, wọn rẹ ara wọn sílẹ̀ tàbí fi ìtẹríba hàn tàbí wọn ó tẹ̀òfin àti àṣẹ mo pa fún un yín àti àwọn baba yín.

11 "Fún ìdí èyí, báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run àwọn Israẹli : Mo ti pinnu láti ibi orí yín àti láti pa Juda run. 12 Èmi yóò àwọn èérún ó Juda, wọ́n ṣetán láti lọ Ejibiti. Wọn yóò ṣubú pẹ̀idà tàbí wọn pẹ̀ìyàn láti orí ọmọdé títí àgbà ni wọn yóò láti ọwọ́ ìyàn tàbí idà. Wọn yóò di ẹni ìfiré àti ìparun, ẹni ̀kọ̀ àti ẹni ̀gàn. 13 Èmi yóò fi ìyà jẹ ẹni ó ń gbé Ejibiti pẹ̀idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn mo ṣe fi ìyà jẹ Jerusalẹmu. 14 èyí ó kéré nínú Juda ó , ó ń gbé ilẹ̀ Ejibiti yóò àsálà padà sórí ilẹ̀ Juda, èyí wọ́n nífẹ̀́ láti padà , àti láti máa gbé; àyàfi àwọn aṣàtìpó mélòó kan."

15 Lẹ́yìn èyí, gbogbo àwọn ọkùnrin mọ̀ , ìyàwó wọn sun tùràrí àwọn òrìṣà pẹ̀àwọn obìnrin ó àwọn ènìyàn púpọ̀, pàápàá àwọn ènìyàn wọ́n ń gbé òkè àti ìsàlẹ̀ Ejibiti, bẹ́̀ ni a fún Jeremiah. 16 "Wọn , àwa fetísílẹ̀ ̀rọ̀ o wa sọ orúkọ Olúwa. 17 Dájúdájú, à ó ṣe gbogbo nǹkan a sọ à ò ṣe. A ó sun tùràrí ayaba ̀run, à ó da ohun mímu sílẹ̀ gẹ́gẹ́ ẹbọ àwa àti àwọn baba wa, àwọn ọba àti àwọn aláṣẹ ti ṣe àwọn ìlú Juda àti ni àwọn ìgboro Jerusalẹmu. Nígbà náà àwa oúnjẹ púpọ̀, a ṣe rere a ibi. 18 Ṣùgbọ́n láti ìgbà a ti dáwọ́ tùràrí sísun Ayaba ̀run àti láti da ẹbọ ohun mímu fún un, àwa ti ṣaláìní ohun gbogbo, a run nípa idà àti nípa ìyàn."

19 Àwọn obìnrin náà fi kún un , "Nígbà à ń tùràrí ayaba ̀run, a ń fi ohun mímu ẹbọ si; ǹjẹ́ àwọn ọkọ wa mọ àwa ń ṣe àkàrà i, àwòrán rẹ, àti à ń da ọtí si gẹ́gẹ́ bi ohun ìrúbọ?"

20 Wàyí o, Jeremiah sọ fún àwọn ̀pọ̀ ènìyàn náà, ọkùnrin àti obìnrin, wọn ń dáhùn , 21 "Ṣe Olúwa rántí ẹbọ sísun ìlú Juda àti àwọn ìgboro Jerusalẹmu láti ̀dọ̀ rẹ àti ̀dọ̀ àwọn baba rẹ, àwọn ọba àti àwọn aláṣẹ àti àwọn ènìyàn ìlú. 22 Nígbà Olúwa fi ara da ìwà búburú yín àti àwọn nǹkan ìríra gbogbo ṣe, ilẹ̀ yín di ohun ìfiré àti ìkọ̀sílẹ̀, láìsí olùgbé gẹ́gẹ́ ó ti ṣe lónìí. 23 Nítorí ti sun ẹbọ, ti ṣẹ̀ Olúwa àti gbọ́rọ̀ i lẹ́nu, àti tẹ̀òfin rẹ̀ àti àwọn àṣẹ. Ibi náà yóò sórí rẹ àti o ṣe i."

24 Nígbà náà ni Jeremiah dáhùn pẹ̀obìnrin náà , "Gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa, ̀yin ọmọ Juda ó Ejibiti. 25 Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli . Ìwọ àti àwọn ìyàwó rẹ fihàn pẹ̀àwọn ìhùwà rẹ àti àwọn ohun ó ṣèlérí nígbà o , Àwa yóò ̀jẹ́ a jẹ́ ṣẹ lórí sísun tùràrí àti dída ẹbọ ohun mímu orí ère Ayaba ̀run.

"Tẹ̀síwájú nígbà náà, ṣe ohun o sọ, o ̀jẹ́ rẹ ṣẹ. 26 Ṣùgbọ́n gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè, gbogbo ̀yin Júù ń gbé ilẹ̀ Ejibiti, mo gégùn ún: Mo búra pẹ̀títóbi orúkọ mi,bẹ́̀ ni Olúwa , ẹnikẹ́ni láti Juda ń gbé ibikíbi Ejibiti ó gbọdọ̀ pe orúkọ mi tàbí búra, "Gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ó wa ti láààyè." 27 Nítorí náà, èmi ó ṣọ wọ́n fún ibi, í ṣe fún rere. Àti gbogbo àwọn ọkùnrin Juda ó ilẹ̀ Ejibiti ni a ó parun pẹ̀idà àti ìyàn títí gbogbo wọn yóò fi tán. 28 Àwọn ó àsálà kúrò lọ́wọ́ ìparun idà àti pípadà ilẹ̀ Juda láti Ejibiti yóò kéré níye. Gbogbo àwọn ó ilẹ̀ Juda, ó gbé ilẹ̀ Ejibiti yóò mọ ̀rọ̀ ẹni yóò dúró yálà tèmi tàbí tiyín.

29 " Èyí ni yóò jẹ́ àmì fún un yín èmi yóò fi ìyà jẹ yín níbi Olúwa ti sọ láti jẹ́ mọ̀ ìjìyà mi mo sọ ̀ ó jẹ yóò ṣẹ.30 Báyìí ni Olúwa : Èmi yóò fi Farao Hofira ọba Ejibiti àwọn ̀rẹ̀ lọ́wọ́, èyí ó pa ayé rẹ́; gẹ́gẹ́ mo ti fi Sedekiah ọba Juda Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́ ̀ń lépa ̀rẹ̀.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também