Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 27

Juda yóò sin Nebukadnessari

1 ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ìṣèjọba Sedekiah ọmọ Josiah ọba Juda, ̀rọ̀ yìí tọ Jeremiah láti ̀dọ̀ Olúwa . 2 Èyí ni ohun Olúwa , "Ṣe àjàgà àti ̀irin fún ara rẹ, o fiwé ọrùn rẹ. 3 o rán ̀rọ̀ ọba ti Edomu, Moabu, Ammoni, Tire àti Sidoni láti ọwọ́ àwọn ikọ̀ ó Jerusalẹmu sọ́dọ̀ Sedekiah ọba Juda. 4 o pàṣẹ fún wọn láti fún àwọn olúwa wọn , Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli : "Sọ èyí fún àwọn olúwa rẹ. 5 Pẹ̀agbára ńlá mi àti ọwọ́ nínà mi ni Èmi ayé, ènìyàn àti ẹranko ó lórí ilẹ̀ ayé, mo fún ẹni ó wu ọkàn mi. 6 Nísinsin yìí, Èmi yóò fa gbogbo orílẹ̀-èdè rẹ fún Nebukadnessari ọba Babeli ìránṣẹ́ mi; Èmi yóò àwọn ẹranko búburú wọ̀n-ọn-nì jẹ́ tirẹ̀. 7 Gbogbo orílẹ̀-èdè ni yóò máa sìn ín àti àwọn ọmọdọ́mọ rẹ̀ títí ilẹ̀ rẹ yóò fi ; ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè àti àwọn ọba ńlá ni yóò tẹríba fún.

8 " ‘ "Ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan sin Nebukadnessari ọba Babeli, tàbí ó tẹ orí rẹ̀ ba abẹ́ àjàgà rẹ̀, Èmi yóò fi ìyà jẹ orílẹ̀-èdè náà nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, ni Olúwa títí Èmi yóò fi run wọ́n nípa ọwọ́ rẹ̀. 9 Nítorí náà, ṣe tẹ́sílẹ̀ àwọn wòlíì yín, àwọn aláfọ̀ṣẹ yín, àwọn ń rọ́ àlá fún un yín, àwọn oṣó yín, tàbí àwọn àjẹ́ yín wọ́n ń sọ fún un yín , ̀yin sin ọba Babeli.10 Wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ irọ́ fún un yín èyí yóò u yín jìnnà réré kúrò ilẹ̀ yín; Èmi ó yín jáde, ̀yin ó ṣègbé. 11 Ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè kankan tẹ orí rẹ̀ ba lábẹ́ àjàgà ọba Babeli, ó sìn ín, Èmi yóò jẹ́ orílẹ̀-èdè náà lórí ilẹ̀ rẹ̀ láti máa ro ó, àti láti máa gbé ibẹ̀ ni Olúwa ." ’ "

12 Èmi sọ ̀rọ̀ náà fún Sedekiah ọba Juda : "Tẹ orí rẹ ba lábẹ́ àjàgà ọba Babeli, sìn ín ìwọ àti àwọn ènìyàn rẹ, ìwọ yóò . 13 ìwọ àti àwọn ènìyàn rẹ yóò ṣe nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, èyí Olúwa fi ń halẹ̀ mọ́ àwọn orílẹ̀-èdè sin ọba Babeli? 14 ṣe fetísílẹ̀ ̀rọ̀ àwọn wòlíì ó ń sọ , ̀yin sin ọba Babeli,nítorí àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fún un yín. 15 Èmi rán wọn ni Olúwa . Wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké orúkọ mi. Nítorí náà, Èmi yóò wọn, wọn yóò ṣègbé, ̀yin pẹ̀àwọn wòlíì ó ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún un yín.’ "

16 Nígbà náà ni mo sọ fún àwọn àlùfáà àti gbogbo àwọn ènìyàn náà , "Èyí ni ohun Olúwa sọ, ṣe fetí nǹkan àwọn wòlíì ń sọ , Láìpẹ́ ohun èlò ilé Olúwa ni a ó padà láti Babeli,àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ. tẹ́wọn. 17 ṣe tẹ́wọn, máa sin ọba Babeli, ̀yin yóò . Èéṣe ìlú yóò fi di ahoro? 18 wọ́n jẹ́ wòlíì, wọ́n ̀rọ̀ Olúwa, jẹ́ wọ́n bẹ Olúwa àwọn ọmọ-ogun a ṣe ohun èlò ó ilé Olúwa àti ààfin ọba Juda àti Jerusalẹmu lọ Babeli. 19 Nítorí , èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ nípa àwọn opó, omi Òkun ti ìpilẹ̀ṣẹ̀ àti ti ohun èlò ìyókù ó ìlú náà. 20 Èyí Nebukadnessari ọba Babeli lọ nígbà ó Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda lọ ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ Babeli, pẹ̀àwọn ọlọ́Juda àti Jerusalẹmu. 21 Lóòótọ́, èyí ni ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli nípa àwọn ohun ìṣúra ó ṣẹ́ilé Olúwa àti ààfin ọba Juda àti Jerusalẹmu: 22 A ó wọn lọ ilẹ̀ Babeli, ibẹ̀ ni wọn ó títí di ìgbà mo padà,èyí ni ̀rọ̀ Olúwa. Lẹ́yìn èyí, Èmi yóò wọn padà, Èmi yóò ṣe wọ́n lọ́jọ̀ ibí yìí.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também