Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 37

Jeremiah nínú túbú

1 Sedekiah ọmọ Josiah jẹ ọba ipò Jehoiakini ọmọ Jehoiakimu ẹni Nebukadnessari ọba Babeli fi jẹ ọba ilẹ̀ Juda. 2 Ṣùgbọ́n àti òun àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ àti àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà fetísí ̀rọ̀ Olúwa ó sọ nípa wòlíì Jeremiah.

3 Sedekiah ọba rán Jehukali ọmọ Ṣelemiah àti Sefaniah ọmọ Maaseiah Jeremiah wòlíì , "Jọ̀wọ́ gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run wa fún wa."

4 Nígbà yìí Jeremiah ń wọlé, ó ń jáde láàrín àwọn ènìyàn nítorí wọ́n ti fi sínú túbú. 5 Àwọn ọmọ-ogun Farao ti jáde kúrò nílẹ̀ Ejibiti àti nígbà àwọn ará Babeli ń ṣàtìpó Jerusalẹmu gbọ́ ìròyìn nípa wọn, wọ́n kúrò Jerusalẹmu.

6 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wòlíì Ọlọ́run : 7 "Èyí ni, ohun Olúwa Ọlọ́run àwọn Israẹli sọ fún ọba àwọn Juda rán láti wádìí nípa mi. Àwọn ọmọ-ogun Farao jáde láti kún lọ́wọ́ yóò padà sílẹ̀ wọn Ejibiti. 8 Nígbà náà ni àwọn ará Babeli yóò padà láti gbógun ti ìlú. Wọn yóò wọn nígbèkùn, wọn yóò fi iná ìlú náà kanlẹ̀.’

9 "Èyí ni ohun Olúwa , ṣe tan ara yín jẹ èrò , Àwọn ará Babeli yóò fi sílẹ̀ pẹ̀ìdánilójú.Wọn ṣe bẹ́̀. 10 Kódà ṣe wọn yóò ṣẹ́gun àwọn ọmọ-ogun Babeli ń gbóguntì yín àti àwọn ìjàǹbá ṣe, wọ́n ti fi sílẹ̀ ibùdó wọn; wọn yóò jáde láti ìlú náà kanlẹ̀."

11 Lẹ́yìn àwọn ọmọ-ogun Babeli ti kúrò Jerusalẹmu nítorí àwọn ọmọ-ogun Farao. 12 Jeremiah múra láti fi ìlú náà sílẹ̀, láti lọ olú ìlú Benjamini láti gba ̀tọ́ rẹ̀ nínú ohun ìní láàrín àwọn ènìyàn níbẹ̀. 13 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n ẹnu ibodè Benjamini, olórí àwọn olùṣọ́ orúkọ rẹ ń jẹ́ Irijah ọmọ Ṣelemiah ọmọ Hananiah un, ó , "Ìwọ ń fi ara mọ́ àwọn ará Babeli."

14 Jeremiah sọ , "Èyí í ṣe òtítọ́! Èmi yapa àwọn ará Babeli." Ṣùgbọ́n Irijah ko gbọ́ tirẹ̀, dípò èyí a Jeremiah, ó un lọ ̀dọ̀ àwọn ìjòyè. 15 Nítorí náà ni àwọn ìjòyè ṣe bínú Jeremiah, wọ́n jẹ ́ , wọ́n tún fi túbú nílé Jonatani akọ̀nítorí wọ́n ti fi èyí ṣe ilé túbú.

16 Wọ́n fi Jeremiah sínú túbú ó ṣókùnkùn biribiri; níbi ó fún ìgbà pípẹ́. 17 Nígbà náà ni ọba Sedekiah ránṣẹ́ i, ó pàṣẹ wọ́n ààfin níbi ó ti bi í ìkọ̀kọ̀ , "Ǹjẹ́ ̀rọ̀ kan láti ̀dọ̀ Olúwa?"

Jeremiah fèsì , "Bẹ́̀ ni, wọn ó fi ́ ọwọ́ ọba Babeli."

18 Nígbà náà, Jeremiah sọ fún ọba Sedekiah , "Irú ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ yín, àwọn ìjòyè yín pẹ̀àwọn ènìyàn fi sọ sínú túbú? 19 Níbo ni àwọn wòlíì yín wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún un yín ọba Babeli gbóguntì yín ? 20 Ṣùgbọ́n báyìí, olúwa mi ọba, èmí bẹ̀ . Jẹ́ n ̀dùn ọkàn mi tọ̀ ́ ; ṣe rán mi padà ilé Jonatani akọ̀, àfi n síbẹ̀."

21 Ọba Sedekiah pàṣẹ wọ́n fi Jeremiah sínú àgbàlá àwọn ̀ṣọ́, àti wọn fún àkàrà ọjọ́ kọ̀̀kan títí àkàrà ìlú yóò fi tán; bẹ́̀ ni Jeremiah nínú àgbàlá náà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também