Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 35

Àwọn Rekabu

1 ̀rọ̀ ó tọ Jeremiah láti ̀dọ̀ Olúwa ọjọ́ Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda : 2 "Lọ ilé àwọn ọmọ Rekabu, o wọn sọ̀rọ̀, o wọn ilé Olúwa, ̀kan nínú iyàrá wọ̀n-ọn-nì, o fún wọn ọtí wáìnì mu."

3 Nígbà náà ni mo mu Jaaṣaniah ọmọ Jeremiah, ọmọ Habasiniah àti àwọn arákùnrin rẹ̀; àti gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀, àti gbogbo ilé àwọn ọmọ Rekabu. 4 Mo wọn ilé Olúwa sínú iyàrá Hanani ọmọ Igdaliah, ènìyàn Ọlọ́run, ó lẹ́bàá yàrá àwọn ìjòyè, ó òkè yàrá Maaseiah, ọmọ Ṣallumu olùtọ́ẹnu-ọ̀. 5 Mo gbé ìkòkò ó kún fún ọtí wáìnì pẹ̀ago ka iwájú àwọn ọmọ Rekabu. Mo fún wọn , "Mu ọtí wáìnì."

6 Ṣùgbọ́n wọ́n , "Àwa yóò mu ọtí wáìnì nítorí Jonadabu ọmọ Rekabu, baba wa pàṣẹ fún wa : ̀yin gbọdọ̀ mu ọtí wáìnì ̀yin àti àwọn ọmọ yín láéláé. 7 Bẹ́̀ ni, ̀yin gbọdọ̀ kọ́ ilé tàbí fúnrúgbìn, tàbí gbin ọgbà àjàrà. Bẹ́̀ ni ̀yin gbọdọ̀ ̀kankan nínú àwọn ohun wọ̀nyí, ṣùgbọ́n gbogbo ọjọ́ yín ni ̀yin ó máa gbé inú àgọ́; ̀yin ó ọjọ́ púpọ̀ ilẹ̀ náà; níbi ̀yin ti ń ṣe àtìpó.8 Báyìí ni àwa gba ohùn Jehonadabu ọmọ Rekabu baba wa gbọ́ nínú gbogbo èyí ó pàṣẹ fún wa, a mu ọtí wáìnì gbogbo ọjọ́ ayé wa; àwa, àwọn aya wa, àwọn ọmọkùnrin wa, àti àwọn ọmọbìnrin wa. 9 Àti a kọ́ ilé láti gbé; bẹ́̀ ni àwa ọgbà àjàrà tàbí oko, tàbí ohun ̀gbìn. 10 Ṣùgbọ́n àwa ń gbé inú àgọ́, a gbọ́rọ̀, a ṣe gẹ́gẹ́ gbogbo èyí Jonadabu baba wa pàṣẹ fún wa. 11 Ó ṣe, nígbà Nebukadnessari ọba Babeli gòkè ilẹ̀ náà; àwa , , jẹ́ a lọ Jerusalẹmu, nítorí ìbẹ̀ogun àwọn ara Siria.Bẹ́̀ ni àwa ń gbé Jerusalẹmu."

12 Nígbà yìí ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah : 13 "Báyìí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli , lọ, o sọ fún àwọn ọkùnrin Juda, àti àwọn olùgbé Jerusalẹmu , ̀yin yóò ha gba ̀kọ́ láti fetí ̀rọ̀ mi,ni Olúwa . 14 ̀rọ̀ Jehonadabu ọmọ Rekabu ó pàṣẹ fún àwọn ọmọ rẹ̀ wọn gbọdọ̀ mu ọtí wáìnì, ni a ṣẹ, wọn mu ọtí wáìnì títí di òní yìí, nítorí wọ́n gba òfin baba wọn. Èmi ti ń sọ̀rọ̀ fún un yín, ṣùgbọ́n ̀yin fetí mi. 15 Èmi rán gbogbo àwọn ìránṣẹ́ àti àwọn wòlíì yín pẹ̀, "yípadà nísinsin yìí kúrò ̀búburú yín, tún ìṣe yín ṣe rere. ma ṣe bọ òrìṣà tàbí sìn wọ́n; ̀yin ó máa gbé ilẹ̀ náà mo fi fún un yín àti fún àwọn baba ńlá yín." Ṣùgbọ́n ̀yin fetí mi. 16 Nítòótọ́, àwọn ọmọ Jehonadabu ọmọ Rekabu pa òfin baba wọn mọ́ ó pàṣẹ fún wọn, ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn wọ̀nyí pa òfin mi mọ́.’

17 "Nítorí náà, báyìí ni, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli , Fetísílẹ̀! Èmi ó gbogbo ohun búburú èmi ti sọ sórí Juda, àti sórí gbogbo olùgbé Jerusalẹmu nítorí èmi ti wọn sọ̀rọ̀: Ṣùgbọ́n wọn dáhùn.’ "

18 Nígbà náà ni Jeremiah fún ìdílé Rekabu , "Báyìí ni Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli : Nítorí ̀yin gba òfin Jehonadabu baba yín, pa gbogbo rẹ̀ mọ́, ṣe gẹ́gẹ́ èyí ó pàṣẹ fún un yín.19 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli , : Jonadabu ọmọ Rekabu yóò fẹ́ ọkùnrin kan láti sìn .’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também