Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 46

Àṣọtẹ́lẹ̀ nípa Ejibiti

1 46.1-28: Isa 19; El 29.1–32.32; Sk 14.18-19. Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa ó tọ Jeremiah wòlíì nípa àwọn Orílẹ̀-èdè.

2 Nípa Ejibiti.

Èyí ni ̀rọ̀ nípa àwọn ọmọ-ogun Farao Neko ọba Ejibiti ẹni a borí rẹ̀ Karkemiṣi, odò Eufurate láti ọwọ́ Nebukadnessari ọba Babeli ọdún kẹrin Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda:

3 "múra àpáta, èyí ó tóbi, àti èyí ó kéré,

súnmọ́ ojú ìjà!

4 di ẹṣin gàárì,

gùn ún.

dúró lẹ́sẹẹsẹ

pẹ̀àṣíborí yín!

dán ̀kọ̀ yín,

wọ ̀irin.

5 46.5: Jr 6.25; 20.3,10; 49.29; Sm 31.13. ni nǹkan mo tún ?

Wọ́n bẹ̀,

wọ́n ń padà sẹ́yìn,

wọ́n ti ṣẹ́gun àwọn jagunjagun.

Wọ́n ,

wọn bojú wẹ̀yìn,

ìbẹ̀níbi gbogbo,"

ni Olúwa .

6 "Ẹni ó yára yóò le sálọ,

tàbí alágbára àsálà.

àríwá ibi odò Eufurate

wọn yóò kọsẹ̀, wọn yóò ṣubú.

7 "Ta ni èyí ó gòkè odò Ejibiti,

omi rẹ̀ ń ru gẹ́gẹ́ odò wọ̀n-ọn-nì?

8 Ejibiti dìde odò náà,

omi odò ń ru.

Ó , Èmi yóò dìde, n ó bo gbogbo ilẹ̀ ayé.

Èmi yóò pa ìlú àti àwọn ènìyàn rẹ̀ run.

9 gòkè ̀yin ẹṣin,

sáré kíkankíkan ̀yin kẹ̀kẹ́.

àwọn alágbára túbọ̀ tẹ̀síwájú,

àwọn ará Kuṣi àti àwọn ará Puti ń di asà ;

àti àwọn ará Lidia ń fa ọrun.

10 Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà jẹ́ ti Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

ọjọ́ ìgbẹ̀san, ìgbẹ̀san lára àwọn ̀rẹ̀.

Idà yóò jẹ́ títí yóò fi ìtẹ́lọ́rùn,

títí yóò fi pa òǹgbẹ rẹ̀ rẹ́ pẹ̀̀jẹ̀.

Nítorí Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò ẹbọ

ilẹ̀ gúúsù odò Eufurate.

11 "Gòkè lọ Gileadi, o ìkunra,

ìwọ wúńdíá ọmọbìnrin Ejibiti.

Ṣùgbọ́n asán ni ìwọ ń lo oògùn,

yóò ìwòsàn fún .

12 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò gbọ́ nípa ìtìjú rẹ,

igbe rẹ yóò kún gbogbo ayé.

Jagunjagun yóò máa ṣubú lu ara wọn lórí rẹ,

àwọn méjèèjì yóò jọ ṣubú papọ̀."

13 Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa ó Jeremiah wòlíì sọ nípa wíwá Nebukadnessari ọba Babeli láti lọ dojú ìjà kọ Ejibiti:

14 "Kéde èyí Ejibiti, sọ ́ Migdoli,

sọ ́ Memfisi àti Tafanesi:

Dúró ààyè rẹ o múra sílẹ̀,

nítorí idà náà ń pa àwọn ó .

15 Èéṣe àwọn akọni rẹ fi ṣubú?

Wọn le dìde dúró, nítorí Olúwa yóò wọ́n ṣubú.

16 Wọn yóò máa ṣubú léraléra

wọn yóò máa ṣubú lu ara wọn.

Wọn yóò sọ , dìde, jẹ́ a padà

̀dọ̀ àwọn ènìyàn wa àti ilẹ̀ ìbí wa,

kúrò níbi idà àwọn aninilára.

17 Níbẹ̀ ni wọn ó kígbe ,

Ariwo lásán ni Farao ọba Ejibiti pa,

ó ti sọ àǹfààní rẹ̀ .

18 "èmi ti láààyè," ni ọba,

ẹni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun ,

"Nítòótọ́ gẹ́gẹ́ Tabori láàrín àwọn òkè àti

gẹ́gẹ́ bi Karmeli lẹ́bàá Òkun bẹ́̀ ni òun yóò .

19 Ìwọ, ọmọbìnrin ti ń gbé Ejibiti

pèsè ohun èlò ìrìnàjò fún ara rẹ

nítorí Memfisi yóò di ahoro

a ó fi jóná, láìní olùgbé.

20 "Ẹgbọrọ abo màlúù lẹ́Ejibiti

ṣùgbọ́n eṣinṣin ìparun ,

ó láti àríwá.

21 Àwọn jagunjagun rẹ̀

dàbí àbọ́pa akọ màlúù.

Àwọn pẹ̀yóò yípadà,

wọn ó jùmọ̀ ,

wọn le dúró,

nítorí ọjọ́ ibi ń bọ̀ lórí wọn

àsìkò láti jẹ wọ́n ìyà.

22 Ejibiti yóò pòṣé ejò ń

ọmọ-ogun ṣe ń tọ̀ ́ pẹ̀agbára.

Wọn ó tọ̀ ́ pẹ̀àáké,

gẹ́gẹ́ i ti agégi.

23 Wọn o igbó rẹ̀ lulẹ̀," ni Olúwa ,

"nítorí ti a le rídìí rẹ̀.

Nítorí wọ́n pọ̀ ju ẹlẹ́ǹgà lọ, wọ́n jẹ́ àìníye.

24 A ó dójútì ọmọbìnrin Ejibiti,

a ó á ọwọ́ àwọn ènìyàn àríwá."

25 Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli : "Èmi yóò rọ̀ìyà mi sórí Amoni òrìṣà Tebesi, sórí Farao, sórí Ejibiti àti àwọn òrìṣà rẹ̀ àti sórí àwọn ọba rẹ̀ àti sórí àwọn gbẹ́kẹ̀Farao. 26 Èmi ó fi wọ́n àwọn ̀wọn lọ́wọ́, Nebukadnessari ọba Babeli, ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Ejibiti yóò di gbígbé i ti àtijọ́," ni Olúwa .

27 "bẹ̀, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi,

fòyà, ìwọ Israẹli.

Dájúdájú èmi ó gbà ́ láti ̀jíjìn,

àwọn ọmọ ọmọ rẹ ilẹ̀ ìgbèkùn.

Jakọbu yóò tún àlàáfíà àti ààbò,

ṣí ẹni yóò dẹ́rùbà á.

28 bẹ̀, Jakọbu ìránṣẹ́ mi,

nítorí mo pẹ̀rẹ," bẹ́̀ ni Olúwa .

"mo tilẹ̀ pa gbogbo orílẹ̀-èdè run,

láàrín àwọn mo fọ́n yín .

Èmi run yín tán.

Èmi yóò jẹ ́ ìyà lórí òdodo,

èmi yóò jọ̀wọ́ rẹ lọ́wọ́ lọ láìjẹ ́ ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também