Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 13

O aṣọ funfun

1 Èyí ni ohun Olúwa fún mi: "Lọ o ra àmùrè aṣọ ̀gbọ̀, o í mọ́ ̀gbẹ́ rẹ, o ṣe jẹ́ omi ó kàn án." 2 Bẹ́̀ ni mo ra àmùrè gẹ́gẹ́ Olúwa ti , mo í mọ́ ̀gbẹ́ mi.

3 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ nígbà kejì, 4 "àmùrè o , o fiwé ̀gbẹ́ rẹ, o lọ Perati, o lọ pa á mọ́ pàlàpálá òkúta." 5 Nígbà náà ni mo lọ pa á mọ́ Perati gẹ́gẹ́ Olúwa ti fún mi.

6 Lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀, Olúwa sọ fún mi, "Lọ Perati o lọ àmùrè mo o pamọ́ síbẹ̀." 7 Nígbà náà ni mo lọ Perati mo lọ àmùrè mi níbi mo pa á mọ́ , ṣùgbọ́n nísinsin yìí àmùrè náà ti bàjẹ́, wúlò fún ohunkóhun mọ́.

8 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 9 "Èyí ni ohun Olúwa sọ: Bákan náà ni èmi yóò run ìgbéraga Juda àti ìgbéraga ńlá ti Jerusalẹmu. 10 Àwọn ènìyàn búburú ó kùnà láti gbọ́ ̀rọ̀ mi, wọ́n ń lo agídí ọkàn wọn, ó ń rìn tọ àwọn òrìṣà láti sìn wọ́n, àti láti foríbalẹ̀ fún wọn, yóò dàbí àmùrè yìí wúlò fún ohunkóhun. 11 Nítorí a ti lẹ àmùrè mọ́ ̀gbẹ́ ènìyàn, bẹ́̀ ni a lẹ agbo ilé Israẹli àti gbogbo ilé Juda mọ́ mi,ni Olúwa , wọn ó jẹ́ ènìyàn ògo àti ìyìn fún mi, ṣùgbọ́n wọn fẹ́ gbọ́.’

Ọtí Wáìnì

12 "Sọ fún wọn, Èyí ni Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ Israẹli , gbogbo ìgò ni à ó fi ọtí wáìnì kún.wọ́n sọ fún , Ṣé a mọ̀ gbogbo ìgò ni ó yẹ láti bu ọtí wáìnì kún?13 Nítorí náà sọ fún wọn , Èyí ni ohun Olúwa : Èmi yóò fi ìmutípara kún gbogbo olùgbé ilẹ̀ yìí pẹ̀ọba ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi, àwọn àlùfáà, àwọn wòlíì gbogbo àwọn ń gbé Jerusalẹmu. 14 Èmi yóò ti èkínní lu èkejì, àwọn baba àti ọmọkùnrin pọ̀ ni Olúwa . Èmi yóò dáríjì, bẹ́̀ ni èmi yóò ṣàánú, èmi yóò ṣe ìyọ́láti máa pa wọ́n run.’ "

Ìkìlọ̀ oko ẹrú

15 Gbọ́ o fetísílẹ̀,

ṣe gbéraga,

nítorí Olúwa ti sọ̀rọ̀.

16 fi ògo fún Olúwa Ọlọ́run yín,

ó òkùnkùn ,

àti ó ẹsẹ̀ yín tàsé

lórí òkè ó ṣókùnkùn.

Nígbà ̀yin ń retí ìmọ́lẹ̀,

òun yóò sọ ́ di òjìji yóò ṣe bi òkùnkùn biribiri.

17 Ṣùgbọ́n ̀yin fetísílẹ̀,

Èmi yóò sọkún ìkọ̀kọ̀

nítorí ìgbéraga yín.

Ojú mi yóò sun ẹkún kíkorò,

omi ẹkún, yóò máa sàn jáde,

nítorí a agbo Olúwa lọ ìgbèkùn.

18 Sọ fún ọba àti ayaba ,

"rẹ ara yín sílẹ̀,

sọ̀kalẹ̀ láti orí ìtẹ́ yín,

adé ògo yín bọ́ ilẹ̀ láti orí yín."

19 Àwọn ìlú ó gúúsù ni à ó pa,

ẹnikẹ́ni láti ṣí wọn.

Gbogbo Juda ni a ó lọ ilẹ̀ ìgbèkùn,

gbogbo wọn ni a ó lọ ìgbèkùn pátápátá.

20 Gbé ojú rẹ sókè,

o wo àwọn ó ń bọ̀ láti àríwá.

Níbo ni agbo ẹran a fi abẹ́ àkóso rẹ ;

àgùntàn ò ń yangàn.

21 ni ìwọ yóò nígbà Olúwa dúró lórí rẹ

àwọn o ̀rẹ́ àtàtà.

Ǹjẹ́ jẹ́ ìrora fún

aboyún ń rọbí?

22 o bi ara rẹ léèrè,

"ni ìdí rẹ̀ èyí fi ṣẹlẹ̀ mi?"

̀pọ̀lọpọ̀ ̀ṣẹ̀ o ṣẹ̀

ni aṣọ rẹ fi fàya

a ṣe é ìṣekúṣe.

23 Ǹjẹ́ Etiopia le àwọ̀ rẹ̀ padà?

Tàbí ẹkùn àwọ̀ rẹ̀ padà?

èyí ti bẹ́̀

náà ni ̀yin ìwà búburú ti mọ́ lára ṣe rere.

24 "N ó fọ́n ọn yín i ìyàngbò

̀fúùfù ilẹ̀ aṣálẹ̀ ń fẹ́.

25 Èyí ni ìpín tìrẹ;

mo ti fi sílẹ̀ fún ,"

ni Olúwa ,

"Nítorí ìwọ ti gbàgbé mi

o gbẹ́kẹ̀àwọn ọlọ́run àjèjì.

26 N ó aṣọ lójú rẹ,

̀sín rẹ le hàn síta

27 ìwà àgbèrè àti ìfẹ́kúfẹ̀́,

àìlójútì panṣágà rẹ!

Mo ti ìwà ìríra rẹ,

lórí òkè àti pápá.

Ègbé ni fún ìwọ Jerusalẹmu!

Yóò ti pẹ́ o ó fi máa àìmọ́?"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também