Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 14

Àjàkálẹ̀-ààrùn, ìyàn àti idà

1 Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa Jeremiah nípa ti àjàkálẹ̀-ààrùn:

2 "Juda káàánú,

àwọn ìlú rẹ̀ kérora

wọ́n pohùnréré ẹkún fún ilẹ̀ wọn,

igbe wọn gòkè lọ láti Jerusalẹmu.

3 Àwọn ọlọ́ènìyàn rán àwọn ìránṣẹ́ wọn lọ bu omi,

wọ́n lọ ìdí àmù

ṣùgbọ́n wọn omi.

Wọ́n padà pẹ̀ìkòkò òfìfo;

ìrẹ̀wẹ̀àti àìnírètí wọn,

wọ́n bo orí wọn.

4 Ilẹ̀ náà sán

nítorí òjò ilẹ̀ náà;

ìrètí àwọn àgbẹ̀ di òfo,

wọ́n bo orí wọn.

5 Kódà, abo àgbọ̀nrín ó lórí pápá

fi ọmọ rẹ̀ ó ṣẹ̀ṣẹ̀ sílẹ̀,

torí koríko.

6 Àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó dúró lórí òkè òfìfo

wọ́n ń ̀fúùfù ìkookò

ojú wọn ríran

nítorí koríko jíjẹ."

7 ó tilẹ̀ jẹ́ ̀ṣẹ̀ wa jẹ́rìí lòdì wa,

nǹkan kan ṣe i Olúwa, nítorí orúkọ rẹ.

Nítorí ìpadàsẹ́yìn wa ti pọ̀,

a ti ṣẹ̀ .

8 Ìrètí Israẹli;

ìgbàlà rẹ lásìkò ìpọ́njú,

èéṣe ìwọ dàbí àlejò ilẹ̀ náà

arìnrìn-àjò ó dúró fún òru ọjọ́ kan péré?

9 Èéṣe ìwọ dàbí ẹni a dààmú,

jagunjagun le ran ni lọ́wọ́?

Ìwọ láàrín wa, Olúwa,

orúkọ rẹ ni a ń mọ́ wa;

ṣe fi sílẹ̀.

10 Báyìí ni Olúwa sọ nípa àwọn ènìyàn wọ̀nyí:

"Wọ́n fẹ́ràn láti máa rìn kiri;

wọn ọkàn wọn ìjánu.

Nítorí náà Olúwa gbà wọ́n;

yóò rántí ìwà búburú wọn báyìí,

yóò fi ìyà ̀ṣẹ̀ wọn jẹ wọ́n."

11 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún mi , "ṣe gbàdúrà fún àlàáfíà àwọn ènìyàn wọ̀nyí. 12 14.12: If 6.8.ó tilẹ̀ jẹ́ wọ́n gbààwẹ̀, èmi tẹ́igbe wọn. ó tilẹ̀ jẹ́ wọ́n ẹbọ sísun àti ẹbọ ìyẹ̀fun, èmi ò nígbà wọ́n. Dípò bẹ́̀, èmi ó fi idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn pa wọ́n run."

13 Ṣùgbọ́n mo sọ , "Háà! Olúwa Olódùmarè. Àwọn wòlíì ń sọ fún wọn , ni idà tàbí ìyàn. Dájúdájú èmi ó fún yín àlàáfíà yóò tọ́jọ́ níbí yìí?’ "

14 Nígbà náà Olúwa sọ fún mi , "Àwọn wòlíì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké orúkọ mi. Èmi rán wọn, tàbí yàn wọ́n tàbí wọn sọ̀rọ̀. Ìran èké ni wọ́n ń i yín. Àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fún un yín nípa ìran ìrírí, àfọ̀ṣẹ, ìbọ̀rìṣà àti ìtànjẹ ọkàn wọn. 15 Nítorí náà, èyí ni Olúwa sọ nípa àwọn wòlíì wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ lórúkọ mi. Èmi rán wọn, síbẹ̀ wọ́n ń sọ , Idà kan tàbí ìyàn, yóò ilẹ̀ yìí.Àwọn wòlíì kan náà yóò parẹ́ nípa idà àti ìyàn. 16 Bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún ni a ó òpópónà Jerusalẹmu torí idà àti ìyàn. Wọn i ẹni yóò sìn wọ́n tàbí ìyàwó wọn, àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn. Èmi yóò ìdààmú ó yẹ ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn.

17 "ìwọ ó sọ ̀rọ̀ yìí fún wọn :

" Jẹ́ ojú mi ó sun omijé

̀sán àti òru láìdá;

nítorí a ti ṣá wúńdíá,

ọmọ ènìyàn mi ọgbẹ́ ńlá

pẹ̀lílù bolẹ̀.

18 mo lọ orílẹ̀-èdè náà,

Èmi yóò àwọn wọ́n fi idà pa.

mo lọ ìlú ńlá,

èmi àwọn ìyàn ti sọ di aláàrùn.

Wòlíì àti Àlùfáà

ti lọ ilẹ̀ wọn mọ̀.’ "

19 Ṣé o ti kọ Juda sílẹ̀ pátápátá ni?

Ṣé o ti ṣá Sioni ?

Èéṣe o fi pọ́n wa lójú

a fi le sàn?

A ń retí àlàáfíà

ṣùgbọ́n ohun rere kan ì ,

àsìkò ìwòsàn

ìpayà ń .

20 Olúwa, a jẹ́wọ́ ìwà ibi wa

àti àìṣedéédéé àwọn baba wa;

lóòótọ́ ni a ti ṣẹ̀ .

21 Nítorí orúkọ rẹ ṣe kórìíra wa;

ṣe sọ ìtẹ́ ògo rẹ di àìlọ́wọ̀.

Rántí májẹ̀o wa

o ṣe á.

22 Ǹjẹ́ èyíkéyìí àwọn òrìṣà yẹ̀yẹ́ àwọn orílẹ̀-èdè le ṣe òjò rọ̀?

Ǹjẹ́ àwọsánmọ̀ fúnra rẹ̀ rọ òjò ?

Rárá, ìwọ ni, Olúwa Ọlọ́run wa.

Torí náà, ìrètí wa lọ́dọ̀ rẹ,

nítorí ìwọ lo ń ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também