Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 8

1 " ìgbà náà ni Olúwa , wọn yóò egungun àwọn ọba Juda àti egungun àwọn ìjòyè, egungun àwọn àlùfáà àti egungun àwọn wòlíì àti egungun àwọn olùgbé Jerusalẹmu kúrò nínú ibojì. 2 A ó yọ wọ́n síta fún oòrùn àti òṣùpá àti gbogbo àwọn ìràwọ̀ ojú ̀run wọ́n ti fẹ́ràn wọ́n ti sìn, àti àwọn wọ́n ti tọ̀ lẹ́yìn wọ́n ti wọ́n ti foríbalẹ̀ fún. yóò ṣà wọ́n jọ tàbí sìn wọ́n, wọn yóò dàbí ìdọ̀lórí ilẹ̀. 3 Níbikíbi mo wọn lọ, gbogbo àwọn ìyókù wọn yóò fẹ́ ikú ju ìyè lọ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun .

̀ṣẹ̀ àti ìjìyà

4 "fún wọn , Èyí ni ohun Olúwa :

" ènìyàn ṣubú lulẹ̀, wọn í padà dìde ?

Nígbà ènìyàn kúrò ̀rẹ, í padà ?

5 Èéṣe nígbà náà àwọn ènìyàn wọ̀nyí fi kúrò lọ́rẹ̀?

Jerusalẹmu fi kúrò gbogbo ìgbà?

Wọ́n rọ̀ mọ́ ̀tàn;

wọ́n kọ̀ láti yípadà.

6 Mo ti fetísílẹ̀ dáradára,

wọn sọ ohun ó tọ́.

ẹnìkan ronúpìwàdà nínú ìwà búburú rẹ̀,

ó , "ni mo ṣe?"

Olúkúlùkù ń tọ ̀rẹ̀

gẹ́gẹ́ ẹṣin ń lọ sójú ogun.

7 Kódà, ẹyẹ àkọ̀ ojú ̀run

mọ ìgbà tirẹ̀,

àdàbà, alápáǹdẹ̀dẹ̀ àti lékèélékèé

mọ àkókò ìṣípò padà wọn.

Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi mọ

ohun Olúwa wọn fẹ́.

8 " Báwo ni ̀yin ṣe , "Àwa gbọ́n,

nítorí a òfin Olúwa,"

nígbà ó jẹ́ kálámù èké àwọn akọ̀

ti àwọn sọ ́ di ̀tàn.

9 Ojú yóò ti àwọn ọlọ́gbọ́n,

a ó wọ́n láàmú, wọn yóò ìgbèkùn.

Nítorí wọ́n ti kọ ̀rọ̀ Olúwa,

irú ọgbọ́n wo wọ́n ?

10 Nítorí náà, èmi yóò fi ìyàwó wọn fún àwọn ọkùnrin mìíràn

àti ilẹ̀ wọn fún àwọn ẹlòmíràn.

Láti èyí kéré èyí dàgbà ,

gbogbo wọn ni èrè àjẹjù ń jẹ lógún;

àwọn wòlíì àti àwọn àlùfáà

pẹ̀ń hùwà ̀tàn.

11 Wọ́n tọ́ọgbẹ́ àwọn ènìyàn mi

gẹ́gẹ́ èyí jinlẹ̀.

"Àlàáfíà, àlàáfíà," ni wọ́n ń ,

nígbà àlàáfíà.

12 Ǹjẹ́ wọ́n tijú fún ìṣe ìríra wọn?

Bẹ́̀ kọ́, wọn ìtìjú rárá;

wọn tilẹ̀ mọ wọ́n ti ṣe ń .

Nítorí náà wọn yóò ṣubú pẹ̀àwọn ti ṣubú,

a ó wọ́n lulẹ̀ nígbà a bẹ̀ wọ́n ,

ni Olúwa .

13 " Èmi yóò ìkórè wọn kúrò,

ni Olúwa .

yóò èso lórí igi àjàrà.

yóò ̀pọ̀tọ́ lórí igi,

ewé wọn yóò rẹ̀ sílẹ̀.

Ohun mo ti fi fún wọn

ni à ó gbà kúrò.’ "

14 "Èéṣe àwa fi jókòó ibí yìí?

A ara wa jọ!

Jẹ́ a sálọ ìlú olódi

a ṣègbé síbẹ̀.

Nítorí Olúwa Ọlọ́run wa ti pinnu a ó ṣègbé.

Yóò fún wa omi onímájèlé mu,

nítorí àwa ti ṣẹ̀ i.

15 Àwa ń retí àlàáfíà

ìre kan,

ó ìgbà ìmúláradá

ṣe ìpayà nìkan.

16 Ìró ìfọn imú ẹṣin àwọn ọlọ̀tẹ̀

ń gbọ́ láti Dani,

yíyan àwọn akọ ẹṣin

gbogbo ilẹ̀ wárìrì.

Wọ́n láti pa ilẹ̀ náà run,

gbogbo ohun níbẹ̀,

ìlú náà àti gbogbo olùgbé ibẹ̀.

17 "ó, èmi yóò rán àwọn ejò olóró àárín yín,

paramọ́lẹ̀ pa oró wọn,

yóò yín jẹ,"

ni Olúwa .

18 Olùtùnú mi, nígbà ìbànújẹ́ ọkàn mi,

rẹ̀wẹ̀nínú mi.

19 Fetí ẹkún àwọn ènìyàn mi

láti ilẹ̀ jíjìnnà :

"Olúwa ha Sioni ?

Ọba rẹ̀ níbẹ̀ mọ́ ni?"

"Èéṣe wọ́n fi mi bínú pẹ̀ère wọn,

pẹ̀àwọn òrìṣà àjèjì wọn níláárí?"

20 "Ìkórè ti rékọjá,

ìgbà ̀̀rùn ti parí,

síbẹ̀ a gbà ."

21 Níwọ́n ìgbà a pa àwọn ènìyàn mi run, èmi náà run pẹ̀,

èmi ṣọ̀fọ̀, ìrora mi káká.

22 ha ìkunra Gileadi ?

ha àwọn oníṣègùn níbẹ̀?

ha fi ìwòsàn

fún ọgbẹ́ àwọn ènìyàn mi?

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também