Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 12

̀rọ̀ Jeremiah

1 Olúwa, olódodo ni ́ nígbàkígbà,

nígbà mo ẹjọ́ kan tọ̀ ́ .

Síbẹ̀ èmi yóò sọ̀rọ̀ nípa òdodo rẹ.

Èéṣe ̀àwọn ènìyàn búburú fi ń ṣe déédé?

Èéṣe gbogbo àwọn aláìṣòdodo ń gbé ìrọ̀rùn?

2 Ó ti gbìn wọ́n, wọ́n ti fi egbò múlẹ̀,

wọ́n dàgbà wọ́n so èso.

Gbogbo ìgbà ni ó ètè wọn,

o jìnnà ọkàn wọn.

3 Síbẹ̀ o mọ̀ Olúwa,

o ti mi o ti dán èrò mi nípa rẹ .

Wọ, wọ́n lọ àgùntàn a fẹ́ pa.

wọ́n sọ́tọ̀ fún ọjọ́ pípa.

4 Yóò ti pẹ́ ̀gbẹlẹ̀ yóò fi ,

gbogbo ewéko igbó ń rọ?

Nítorí àwọn ènìyàn búburú ni ó ń gbé ibẹ̀.

Àwọn ẹranko àti àwọn ẹyẹ ti ṣègbé,

pẹ̀lúpẹ̀àwọn ènìyàn ń sọ ,

"ohun ṣẹlẹ̀ wa."

Ìdáhùn Ọlọ́run

5 ìwọ ń ẹlẹ́ṣẹ̀ sáré,

àárẹ̀ ,

báwo ni ìwọ yóò ṣe ẹṣin díje?

ìwọ kọsẹ̀ ilẹ̀ àlàáfíà,

ìwọ ìgbẹ́kẹ̀,

ni ìwọ ó ṣe nínú ẹkùn odò Jordani?

6 Àwọn arákùnrin rẹ àti àwọn

ìdílé

ti ́, kódà wọ́n ti kẹ̀yìn ,

wọ́n ti lórí.

ṣe gbà wọ́n gbọ́

ó tilẹ̀ jẹ́ wọ́n ń sọ̀rọ̀ rẹ dáradára.

7 Èmi yóò kọ ilé mi sílẹ̀,

èmi yóò fi ìní mi sílẹ̀.

Èmi yóò fi ẹni mo fẹ́

àwọn ̀rẹ̀ lọ́wọ́.

8 Ogún mi ti mi

i kìnnìún nínú igbó.

Ó ń ramúramù mọ́ mi;

nítorí náà mo kórìíra rẹ̀.

9 Ogún mi ha ti mi

ẹyẹ kannakánná

àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dòyì ka, wọ́n kọjú ìjà i?

lọ, gbogbo ẹranko igbó jọ,

wọn jẹ.

10 ̀pọ̀lọpọ̀ olùṣọ́-àgùntàn ni yóò ba ọgbà àjàrà mi jẹ́,

wọn yóò tẹ oko mi mọ́lẹ̀;

wọ́n ó sọ oko dídára mi di

ibi a ń da ìdọ̀.

11 A ó sọ ́ di aṣálẹ̀ ilẹ̀

wúlò níwájú mi,

gbogbo ilẹ̀ ni yóò di ahoro

nítorí ẹnìkankan yóò náání.

12 Gbogbo ibi gíga ó nínú aṣálẹ̀

ni àwọn apanirun ti gorí,

nítorí idà Olúwa yóò pa

láti ìkangun kìn-ín-ní ìkangun èkejì ilẹ̀ náà;

àlàáfíà fún gbogbo alààyè.

13 Àlìkámà ni wọn yóò gbìn, ṣùgbọ́n ̀gún ni wọn yóò ,

wọn yóò fi ara wọn ṣe wàhálà, ṣùgbọ́n òfo ni èrè wọn.

ojú ó yín nítorí èrè yín,

nítorí ìbínú gbígbóná Olúwa.

14 Èyí ni ohun Olúwa : "ti gbogbo àwọn aládùúgbò mi búburú wọ́n gbẹ́sẹ̀ ogún mo fún àwọn ènìyàn Israẹli mi, Èmi yóò wọ́n tu kúrò lórí ilẹ̀ wọn, èmi yóò fa ìdílé Juda tu kúrò àárín wọn. 15 Ṣùgbọ́n mo wọ́n tu tán, Èmi yóò padà yọ́wọn. Èmi yóò padà fún oníkálùkù ogún ìní rẹ̀ pẹ̀ilẹ̀ ìní oníkálùkù. 16 wọ́n kọ ìwà àwọn ènìyàn mi, wọ́n fi orúkọ mi búra , Níwọ̀n Olúwa ń bẹ láààyè,gẹ́gẹ́ wọ́n ti kọ́ àwọn ènìyàn mi láti fi Baali búra, nígbà náà ni a ó gbé wọn láàrín àwọn ènìyàn mi. 17 Ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè kan gbọ́, Èmi yóò á tu pátápátá, èmi yóò pa wọ́n run," ni Olúwa .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também