Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 7

̀sìn àìṣòótọ́ níláárí

1 Èyí ni ̀rọ̀ tọ Jeremiah láti ̀dọ̀ Olúwa. 2 "Dúró ẹnu-ọ̀ilé Olúwa o kéde ̀rọ̀ :

" gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa gbogbo ̀yin ará Juda ń gba ̀wọlé láti sin Olúwa. 3 Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli : Tún àwọn ̀yín ṣe, èmi yóò jẹ́ gbé ilẹ̀ yìí. 4 ṣe gba ̀rọ̀ ̀tàn gbọ́ , "Èyí ni tẹmpili Olúwa ilé tẹmpili Olúwa, ilé tẹmpili Olúwa!" 5 ̀yin tún ̀yín àti iṣẹ́ yín ṣe nítòótọ́, ń ara yín ̀tọ́. 6 fi ara ni àwọn àlejò, àwọn ọmọ aláìní baba àti àwọn opó ta ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ ibí yìí, tọ ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn ìpalára ara yín. 7 Nígbà náà ni èmi yóò jẹ́ gbé ìbí yìí, nílẹ̀ mo fún àwọn baba ńlá yín títí láé. 8 ó, ń gba ̀rọ̀ ̀tàn níláárí gbọ́.

9 " ̀yin yóò ha jalè, pànìyàn, ṣe panṣágà, búra èké, sun tùràrí Baali, tọ ọlọ́run mìíràn ̀yin mọ̀ lọ? 10 Nígbà náà ni ó dúró iwájú nínú ilé yìí a fi orúkọ mi , "àwa ," àwa láti ṣe gbogbo àwọn nǹkan ìríra wọ̀nyí ? 11 7.11: Mt 21.13; Mk 11.17; Lk 19.46.Ṣé ilé yìí, a fi orúkọ mi ti di ihò àwọn ọlọ́ṣà lọ́dọ̀ yín ni? Èmi ti ń ó! ni Olúwa .

12 " lọ nísinsin yìí Ṣilo níbi ti mo kọ́ fi ṣe ibùgbé fún orúkọ mi, ohun mo ṣe i nítorí ìwà búburú Israẹli í ṣe ènìyàn mi. 13 Nígbà ̀yin ń ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí ni èmi a yín sọ̀rọ̀ léraléra ni Olúwa ̀yin gbọ́, èmi yín, ̀yin dáhùn. 14 Nítorí náà, èmi yóò ṣe ohun mo ṣe Ṣilo ilé náà a fi orúkọ mi , ilé tẹmpili nínú èyí ìgbẹ́kẹ̀, ààyè mo fún ̀yin àti àwọn baba yín. 15 Èmi yóò kúrò iwájú mi gẹ́gẹ́ mo ti ṣe àwọn arákùnrin yín, àwọn ará Efraimu.

16 "Nítorí náà ṣe gbàdúrà fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí tàbí o bẹ̀bẹ̀ fún wọn; ma ṣe bẹ̀ , nítorí èmi yóò tẹ́. 17 Ṣé ìwọ ohun wọ́n ń ṣe àwọn ìlú Juda àti òpópó Jerusalẹmu? 18 Àwọn ọmọ ṣa igi jọ, àwọn baba fi iná i, àwọn ìyá po ìyẹ̀fun láti ṣe àkàrà fún ayaba ̀run, wọ́n ẹbọ ọrẹ mímu àwọn ọlọ́run àjèjì láti ru bínú mi sókè. 19 Ṣùgbọ́n ṣe èmi ni wọ́n fẹ́ bínú? ni Olúwa . Ǹjẹ́ í ṣe wọ́n kúkú ń pa ara wọn lára ìtìjú ara wọn?

20 " Nítorí náà, èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè , "Èmi yóò ìbínú àti ìrunú mi orílẹ̀ yìí ènìyàn àti ẹranko, igi, pápá àti èso orí ilẹ̀, yóò ṣe é pa."

21 " Èyí ni Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli : Tẹ̀síwájú ẹbọ sísun yín àti àwọn ẹbọ yòókù papọ̀ ̀yin ó jẹ ẹran wọ́n fúnra yín. 22 tòsí nígbà mo àwọn baba ńlá yín jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti mo wọn sọ̀rọ̀. N pàṣẹ fún wọn lórí ẹbọ sísun lásán. 23 Mo pàṣẹ fún wọn báyìí ; gbọ́ tèmi, èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run yín ̀yin yóò jẹ́ ènìyàn mi. Máa rìn ojú ̀mo pàṣẹ fún yín, ó dára fún yín. 24 Ṣùgbọ́n wọn gbọ́, wọn fetísílẹ̀ dípò èyí wọ́n ń tẹ̀ ̀agídí ọkàn wọn. Dípò wọn tẹ̀síwájú wọ́n ń rẹ̀yìn. 25 Láti ìgbà àwọn baba ńlá yín ti jáde Ejibiti títí di òní, ni èmi ti ń rán àwọn ìránṣẹ́ mi, àwọn wòlíì yín. 26 Wọn gbọ́ wọn fetísílẹ̀. Wọ́n wa ọrùn le, wọn wa ọrùn , wọ́n hu ìwà ìbàjẹ́ ju àwọn baba ńlá wọn.

27 "Nígbà ìwọ sọ gbogbo èyí fún wọn, wọn yóò gbọ́ tirẹ̀, nígbà ìwọ wọ́n, wọn yóò dáhùn. 28 Nítorí náà, sọ fún wọn , Èyí ni orílẹ̀-èdè gbọ́ ti Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ tàbí ó ṣe ìgbọ́ràn ìbáwí. ̀rọ̀ òtítọ́ ètè wọn.

29 " irun yín dàánù, pohùnréré ẹkún lórí òkè, nítorí Olúwa ti kọ ìran yìí ó lábẹ́ ìbínú rẹ̀ sílẹ̀.

Àfonífojì ìparun

30 " Àwọn ènìyàn Juda ti ṣe búburú lójú mi, ni Olúwa . Wọ́n ti to àwọn ère ìríra wọn jọ ilé a fi orúkọ mi wọ́n ti sọ ́ di àìmọ́. 31 Wọ́n ti kọ́ àwọn ibi gíga ti Tofeti àfonífojì Beni-Hinnomu láti sun àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn nínú iná èyí èmi pàṣẹ ọkàn mi. 32 Nítorí náà kíyèsára ọjọ́ ń bọ̀, ni Olúwa , nígbà àwọn ènìyàn é Tafeti tàbí àfonífojì ti Beni-Hinnomu; ṣùgbọ́n yóò ma jẹ àfonífojì ìparun, nítorí wọn yóò sin òkú Tofeti títí fi ààyè mọ́. 33 Nígbà náà ni òkú àwọn ènìyàn wọ̀nyí yóò di oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ojú ̀run àti ẹranko ilẹ̀, ẹnìkan yóò dẹ́rùbà wọ́n. 34 7.34: If 18.23.Èmi yóò òpin ìró ayọ̀ àti ìdùnnú àti ohùn àwọn tọkọtaya àwọn ìlú Juda àti ìgboro Jerusalẹmu, nítorí ilẹ̀ náà yóò di ahoro.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também