Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 26

Wọ́n fi ikú halẹ̀ mọ́ Jeremiah

1 ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ìjọba ọba Jehoiakimu ọmọ Josiah ń ṣe ọba Juda, ̀rọ̀ yìí láti ̀dọ̀ Olúwa: 2 "Èyí ni ohun Olúwa , Dúró àgbàlá ilé Olúwa, o sọ fún gbogbo ènìyàn ilẹ̀ Juda ó ti láti jọ́sìn ilé Olúwa, sọ fún gbogbo ohun mo pàṣẹ fún ; ṣaláìsọ gbogbo ̀rọ̀ náà. 3 Bóyá gbogbo wọn máa gbọ́ ̀rọ̀ náà ̀kọ̀̀kan wọn yóò kúrò nínú ìwà búburú wọn. Èmi ó ọkàn padà, n fi ibi mo ti wọn ṣe wọ́n. 4 Sọ fún wọn , Èyí ni ohun Olúwa : fi etí ̀rọ̀ mi, gbọ́ òfin mi, ti mo gbé kalẹ̀ níwájú yín, 5 àti gbọ́ ̀rọ̀ àwọn ìránṣẹ́ mi, àwọn wòlíì mo rán i yín léraléra (ṣùgbọ́n ̀yin gbọ́), 6 nígbà náà ni èmi yóò ṣe ilé yìí Ṣilo, èmi yóò ṣe ìlú yìí ìfibú gbogbo orílẹ̀-èdè ayé.’ "

7 Àwọn àlùfáà, àwọn wòlíì àti gbogbo ènìyàn ni ó gbọ́ ̀rọ̀ Jeremiah ó sọ ilé Olúwa. 8 Ṣùgbọ́n kété Jeremiah ti parí ̀rọ̀ rẹ̀ Olúwa pàṣẹ láti sọ; àwọn àlùfáà, àti gbogbo ènìyàn dìímú, wọ́n , "Kíkú ni ìwọ yóò ! 9 ìwọ ṣe sọ àsọtẹ́lẹ̀ orúkọ Olúwa , ilé yìí yóò dàbí Ṣilo, orílẹ̀-èdè yìí yóò di ahoro yóò olùgbé." Gbogbo àwọn ènìyàn kójọpọ̀ pẹ̀Jeremiah nínú ilé Olúwa.

10 Nígbà àwọn aláṣẹ Juda gbọ́ nípa nǹkan wọ̀nyí, wọ́n lọ láti ààfin ọba ilé Olúwa, wọ́n ààyè wọn, wọ́n jókòó ẹnu-ọ̀tuntun ilé Olúwa. 11 Àwọn àlùfáà àti àwọn wòlíì sọ fún àwọn aláṣẹ àti gbogbo ènìyàn , "Arákùnrin yìí gbọdọ̀ gba ìdájọ́ ikú nítorí ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ lórí ìlú yìí: ̀yin ti fi etí yín gbọ́!"

12 Nígbà náà ni Jeremiah sọ fún gbogbo àwọn aláṣẹ àti gbogbo àwọn ènìyàn : "Olúwa rán mi láti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ilé yìí àti ìlú yìí, gbogbo ohun ti gbọ́. 13 Nísinsin yìí, tún ̀rẹ ṣe àti ìṣe rẹ, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run yín. Olúwa yóò ọkàn rẹ̀ padà, ohun gbogbo ó ti sọ jáde búburú ṣẹ lórí yín. 14 ó ṣe tèmi ni, èmi ọwọ́ yín, ṣe ohun ̀yin ó dára, ó tọ́ lójú yín fún mi. 15 mọ̀ dájú pa , ó ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sórí ara yín, sórí ìlú yìí àti àwọn olùgbé inú rẹ̀; nítorí nítòótọ́ ni Olúwa ti rán mi láti sọ ̀rọ̀ yìí fún un yín."

16 Nígbà náà ni àwọn aláṣẹ àti gbogbo àwọn ènìyàn sọ fún àwọn àlùfáà àti àwọn wòlíì , "ṣe pa ọkùnrin yìí nítorí ó ti wa sọ̀rọ̀ orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun."

17 Lára àwọn àgbàgbà ilẹ̀ náà sún síwájú, wọ́n sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn náà , 18 "Mika ti Moreṣeti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ọjọ́ Hesekiah ọba Juda. Ó sọ fún gbogbo ènìyàn Juda , Èyí ni ohun Olúwa :

" A ó fa Sioni tu oko

Jerusalẹmu yóò di òkìtì

àlàpà àti òkè ilẹ̀ yìí gẹ́gẹ́

ibi gíga igbó.

19 Ǹjẹ́ Hesekiah ọba Juda tàbí ẹnikẹ́ni Juda pa á ? Ǹjẹ́ Hesekiah bẹ̀Olúwa ó ojúrere rẹ̀? Ǹjẹ́ Olúwa ha a ìpinnu rẹ̀ padà, ibi ó ti sọtẹ́lẹ̀ yẹ̀ kúrò lórí wọn? Ibi ni a fẹ́ sórí ara wa yìí."

20 (Bákan náà Uriah ọmọ Ṣemaiah láti Kiriati-Jearimu jẹ́ ọkùnrin mìíràn ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ kan náà orúkọ Olúwa. Ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ kan náà ìlú náà àti ilẹ̀ yín Jeremiah ti ṣe. 21 Nígbà ọba Jehoiakimu àti gbogbo àwọn aláṣẹ gbọ́ gbogbo ̀rọ̀ rẹ̀, ọba ń láti pa á: ṣùgbọ́n Uriah gbọ́ èyí, ̀á, ó sálọ Ejibiti. 22 Ọba Jehoiakimu rán Elnatani ọmọ Akbori lọ Ejibiti pẹ̀àwọn ọkùnrin mìíràn. 23 Wọ́n Uriah láti Ejibiti lọ ̀dọ̀ ọba Jehoiakimu; ẹni ó fi idà pa, ó sọ òkú rẹ̀ inú isà òkú àwọn ènìyàn lásán.)

24 Ahikamu ọmọ Ṣafani ń bẹ pẹ̀Jeremiah, wọn fi í àwọn ènìyàn lọ́wọ́ láti pa á.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também