Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 20

Jeremiah àti Paṣuri

1 ìgbà àlùfáà Paṣuri ọmọkùnrin Immeri olórí àwọn ìjòyè tẹmpili Olúwa gbọ́ Jeremiah ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nǹkan wọ̀nyí. 2 Ó wọ́n wòlíì Jeremiah, wọ́n fi sínú túbú ó òkè ẹnu-ọ̀ti Benjamini tẹmpili Olúwa. 3 20.3,10: Jr 6.25; 46.5; 49.29; Sm 31.13.ọjọ́ kejì Paṣuri u sílẹ̀ nínú túbú, Jeremiah sọ fún un , "Orúkọ Olúwa fun í ṣe Paṣuri ṣe ìpayà. 4 Nítorí èyí ni ohun Olúwa sọ. Èmi yóò di ̀rùjẹ̀jẹ̀ ara rẹ àti gbogbo àwọn ̀rẹ́ rẹ. ojú ara rẹ, ìwọ yóò wọ́n ṣubú nípa idà ̀wọn. Èmi yóò fi gbogbo àwọn ̀Juda ọba Babeli lọ́wọ́, òun yóò wọn lọ Babeli tàbí ó pa wọ́n. 5 Èmi yóò jọ̀wọ́ gbogbo ọrọ̀ inú ìlú yìí fún ̀wọn. Gbogbo ìní wọ́n gbogbo ọlá ọba Juda. Wọn yóò ru ìkógun lọ Babeli. 6 Àti ìwọ Paṣuri, gbogbo ènìyàn inú ilé rẹ yóò lọ ṣe àtìpó Babeli. Níbẹ̀ ni ìwọ yóò , wọn yóò sin ́ síbẹ̀, ìwọ àti gbogbo àwọn ̀rẹ́ rẹ ìwọ ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ irọ́ fún."

Ìráhùn Jeremiah

7 Olúwa, o tàn jẹ́,

o ṣẹ́gun.

Mo di ẹni ̀gàn gbogbo ọjọ́,

gbogbo ènìyàn fi ṣẹlẹ́.

8 Nígbàkígbà mo sọ̀rọ̀, èmi kígbe síta

èmi á sọ nípa ipá àti ìparun.

Nítorí náà, ̀rọ̀ Olúwa ti àbùkù

àti ̀gàn mi ni gbogbo ìgbà.

9 Ṣùgbọ́n mo sọ , "Èmi yóò dárúkọ rẹ

tàbí sọ nípa orúkọ rẹ̀ mọ́,

̀rọ̀ rẹ̀ ń bẹ bi iná ń nínú mi

nínú egungun mi,

agara mi inú mi

nítòótọ́ èmi ṣe é.

10 Mo gbọ́ sísọ ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́,

ìbẹ̀ni ibi gbogbo.

Fi í sùn! Jẹ́ a fi sùn!

Gbogbo àwọn ̀rẹ́ mi ń dúró

èmi ṣubú, wọ́n ń sọ ,

bóyá yóò jẹ́ di títàn,

nígbà náà ni àwa yóò borí rẹ̀,

àwa yóò gba ̀san wa lára rẹ̀."

11 Ṣùgbọ́n Olúwa ń bẹ pẹ̀mi gẹ́gẹ́ akọni ẹlẹ́.

Nítorí náà, àwọn ó ń lépa mi yóò kọsẹ̀,

wọn yóò borí.

Wọn yóò kùnà, wọn yóò gba ìtìjú púpọ̀.

Àbùkù wọn yóò di ohun ìgbàgbé.

12 Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ìwọ ó ń dán olódodo

o ń ṣe àyẹ̀ọkàn àti ̀fínní fínní,

jẹ́ èmi ó ìgbẹ̀san rẹ lórí wọn,

nítorí ìwọ ni mo gbé ara mi .

13 Kọrin Olúwa!

Fi ìyìn fún Olúwa!

Ó gba ̀àwọn aláìní

lọ́wọ́ àwọn ẹni búburú.

14 Ègbé ni fún ọjọ́ a mi!

ọjọ́ ìyá mi mi ṣe di ti ìbùkún.

15 Ègbé ni fún ọkùnrin ó ìròyìn fún baba mi,

ó ó yọ̀, ó sọ ,

"A ọmọ kan fún ọmọkùnrin!"

16 ọkùnrin náà dàbí ìlú

Olúwa gbàkóso lọ́wọ́ rẹ̀ láìkáàánú

o gbọ́ ariwo ̀fọ̀ àárọ̀,

ariwo ogun ̀sán.

17 Nítorí pa nínú,

ìyá mi dàbí títóbi ibojì mi,

ikùn rẹ̀ di títí láé.

18 Èéṣe mo jáde nínú ikùn,

láti wàhálà àti ̀fọ̀

àti láti parí ayé mi nínú ìtìjú?

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também