Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 36

Jehoiakimu ìwé kíká Jeremiah

1 ọdún kẹrin Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda, ̀rọ̀ yìí tọ Jeremiah láti ̀dọ̀ Olúwa : 2 "ìwé kíká fún ará rẹ, o kọ sínú rẹ̀ gbogbo ̀rọ̀ mo ti sọ nípa Israẹli àti ti Juda, àti gbogbo orílẹ̀-èdè láti ìgbà mo ti sọ fún láti ọjọ́ Josiah títí di òní. 3 Ó jẹ́ ilé Juda yóò gbọ́ gbogbo ibi mo ti pinnu láti ṣe fún wọn; wọn ó yípadà, olúkúlùkù wọn kúrò ̀búburú rẹ̀. èmi ó dárí àìṣedéédéé àti ̀ṣẹ̀ wọn wọ́n."

4 Nígbà náà ni Jeremiah pe Baruku ọmọ Neriah, ó sọ gbogbo ̀rọ̀ Ọlọ́run a sọ fún, Baruku kọ láti ẹnu Jeremiah, gbogbo ̀rọ̀ Olúwa ó ti sọ fún un sórí ìwé kíká náà. 5 Nígbà náà ni Jeremiah fún Baruku , "A mi mọ́! Èmi lọ ilé Olúwa. 6 Nítorí náà, ìwọ lọ ilé Olúwa ọjọ́ àwẹ̀, o nínú ìwé kíká náà ̀rọ̀ Olúwa ìwọ ti ẹnu mi kọ; ìwọ ó á etí gbogbo Juda, wọ́n jáde láti ìlú wọn. 7 Ó jẹ́ , ̀bẹ̀ wọn yóò iwájú Olúwa, wọ́n ó yípadà kúrò ̀búburú wọn; nítorí títóbi ni ìbínú àti ìrunú Olúwa ti sọ àwọn ènìyàn yìí."

8 Baruku ọmọ Neriah ṣe gẹ́gẹ́ gbogbo èyí wòlíì Jeremiah sọ fún, láti ka ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé ilé Olúwa. 9 oṣù kẹsànán ọdún karùn-ún Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda ni wọ́n kéde àwẹ̀ níwájú Olúwa fún gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu àti fún gbogbo àwọn ènìyàn ó láti ìlú Juda. 10 Láti inú yàrá Gemariah ọmọ Ṣafani akọ̀, àgbàlá òkè níbi ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀ilé Olúwa tuntun. Baruku ka ̀rọ̀ Jeremiah láti inú ìwé ilé Olúwa etí gbogbo ènìyàn.

11 Nígbà Mikaiah ọmọ Gemariah ọmọ Ṣafani gbọ́ gbogbo àkọsílẹ̀ ̀rọ̀ Olúwa láti inú ìwé náà; 12 Ó sọ̀kalẹ̀ lọ ilé ọba sínú yàrá akọ̀; níbi gbogbo àwọn ìjòyè gbé jókòó : Eliṣama akọ̀, Delaiah ọmọ Ṣemaiah, Elnatani ọmọ Akbori, Gemariah ọmọ Ṣafani àti Sedekiah ọmọ Hananiah àti gbogbo àwọn ìjòyè. 13 Lẹ́yìn Mikaiah sọ gbogbo ̀rọ̀ wọ̀n-ọn-nì o ti gbọ́ fún wọn, nígbà Baruku láti inú ìwé kíkà náà etí àwọn ènìyàn. 14 Gbogbo àwọn ìjòyè rán Jehudu ọmọ Netaniah ọmọ Ṣelemiah ọmọ Kuṣi Baruku , ìwé kíká náà ọwọ́ rẹ láti inú èyí ìwọ etí àwọn ènìyàn; o si . Nígbà náà ni Baruku ọmọ Neriah ̀dọ̀ wọn pẹ̀ìwé kíká ọwọ́ rẹ̀. 15 Wọ́n fún , "Jókòó, jọ̀wọ́ á etí wa!"

Nígbà náà ni Baruku á etí wọn. 16 Nígbà wọ́n gbọ́ gbogbo ̀rọ̀ náà tan; wọ́n ń wo ara wọn lójú pẹ̀̀. Wọ́n fún Baruku , "Àwa gbọdọ̀ jábọ̀ gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí fún ọba." 17 Wọ́n béèrè lọ́wọ́ Baruku , "Sọ fún wa báwo ni o ṣe kọ gbogbo àwọn ̀rọ̀ wọ̀nyí? Ṣé Jeremiah sọ wọ́n?"

18 Baruku wọn lóhùn , "Bẹ́̀ ni, láti ẹnu rẹ̀ ni, ó sọ gbogbo ̀rọ̀ báyìí fún mi, èmi fi tàdáwà kọ wọ́n sínú ìwé náà."

19 Nígbà náà ni àwọn ìjòyè sọ fún Baruku , "Lọ fi ara rẹ pamọ́ àti Jeremiah, ṣe jẹ́ ẹnìkan mọ ibi ̀yin ."

20 Lẹ́yìn wọ́n fi ìwé kíká náà pamọ́ iyàrá Eliṣama akọ̀, wọ́n wọlé tọ ọba lọ nínú àgbàlá, wọ́n sọ gbogbo ̀rọ̀ náà etí ọba. 21 Ọba rán Jehudu láti lọ ìwé kíká náà , Jehudu mu jáde láti inú iyàrá Eliṣama akọ̀. Ó ka ìwé náà etí ọba àti etí gbogbo àwọn ìjòyè ó dúró ti ọba. 22 Ó jẹ́ ìgbà òtútù nínú oṣù kẹsànán, ọba jókòó ̀iná ààrò, iná náà ń iwájú rẹ̀. 23 Nígbà Jehudu ka ojú ìwé mẹ́ta mẹ́rin nínú ìwé náà, ọba fi ̀bẹ ìwé, ó sọ sínú iná ó nínú ìdáná, títí gbogbo ìwé kíká náà fi jóná tán. 24 Síbẹ̀, ọba àti gbogbo àwọn ̀mẹwà rẹ̀ wọ́n gbọ́ gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí bẹ̀; wọn fa aṣọ wọn . 25 Elnatani, Delaiah àti Gemariah bẹ ọba ó ṣe fi ìwé kíká náà jóná, ṣùgbọ́n ọba kọ̀ láti gbọ́ tiwọn. 26 Dípò èyí ọba pàṣẹ fún Jerahmeeli ọmọ Hameleki, Seraiah ọmọ Asrieli àti Ṣelemiah ọmọ Abdeeli láti Baruku akọ̀àti Jeremiah wòlíì ṣùgbọ́n Olúwa fi wọ́n pamọ́.

27 Lẹ́yìn ọba fi ìwé kíká náà ̀rọ̀ Baruku kọ láti ẹnu Jeremiah jóná tán, ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah : 28 ", tún ìwé kíká mìíràn o kọ gbogbo ̀rọ̀ ó nínú ìwé kíká èkínní Jehoiakimu ọba Juda fi jóná. 29 o fún Jehoiakimu ọba Juda , Báyìí ni Olúwa , ìwọ ti fi ìwé kíká náà jóná, o , "Èéṣe ìwọ fi kọ̀sínú rẹ̀, lóòtítọ́ ni ọba Babeli yóò , yóò pa ilẹ̀ run, àti ènìyàn, àti ẹranko kúrò nínú rẹ̀." 30 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa ti Jehoiakimu ọba Juda , Òun yóò ẹni yóò jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi, à ó sọ òkú rẹ̀ fún ooru ̀sán àti fún òtútù òru. 31 Èmi ó jẹ òun àti irú-ọmọ rẹ̀, ìránṣẹ́ rẹ̀ ìyà nítorí àìṣedéédéé wọn; èmi ó gbogbo ibi èmi ti sọ wọn sórí wọn, àti sórí àwọn olùgbé Jerusalẹmu àti àwọn ènìyàn Juda, nítorí wọn fetísí mi.’ "

32 Nígbà náà ni Jeremiah ìwé kíká mìíràn fún Baruku akọ̀ọmọ Neriah, ẹni ó kọ̀sínú rẹ̀ láti ẹnu Jeremiah gbogbo ̀rọ̀ inú ìwé Jehoiakimu ọba Juda ti sun níná. A fi onírúurú ̀rọ̀ irú èyí kún pẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também