Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 42

1 Nígbà náà gbogbo àwọn olórí ogun àti Johanani ọmọkùnrin Karea àti Jesaniah ọmọkùnrin Hoṣaiah àti kékeré títí orí ẹni ńlá . 2 ̀dọ̀ Jeremiah wòlíì náà, wọ́n sọ fún un , "Jọ̀wọ́ gbọ́ ̀bẹ̀ wa, o gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run rẹ fún gbogbo ìyókù yìí. Nítorí gẹ́gẹ́ bi ìwọ ṣe i nísinsin yìí a pọ̀ níye nígbà kan ; ṣùgbọ́n báyìí àwa díẹ̀ la ṣẹ́. 3 Gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run rẹ sọ ibi àwa yóò lọ fún wa àti ohun àwa yóò ṣe."

4 Wòlíì Jeremiah dáhùn , "Mo ti gbọ́. Èmi yóò gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run yín gẹ́gẹ́ ̀yin ṣe béèrè. Èmi yóò sọ gbogbo ohun Olúwa sọ fún un yín, ń fi ohunkóhun pamọ́ fún un yín."

5 Nígbà náà ni wọ́n sọ fún Jeremiah , "Olúwa ṣe ẹlẹ́rìí òtítọ́ àti òdodo láàrín wa, àwa ṣe gẹ́gẹ́ gbogbo ohun Olúwa Ọlọ́run rẹ rán láti sọ fún wa. 6 Ìbá à ṣe rere, ìbá à ṣe búburú, àwa yóò gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa, èyí àwa ń rán , ó ba à dára fún wa. Nítorí àwa yóò gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa."

7 Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́wàá, ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah , 8 O pe Johanani ọmọkùnrin Karea àti gbogbo àwọn olórí ogun wọ́n pẹ̀rẹ̀; àti gbogbo àwọn ènìyàn láti orí ẹni ó kéré orí ẹni ńlá. 9 Ó fún wọn , "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run àwọn Israẹli : Èyí ni ẹni ̀yin ti rán láti gbé ̀bẹ̀ yín lọ síwájú mi. 10 ̀yin gbé ilẹ̀ yìí, èmi yóò gbé e yín , n yín lulẹ̀, èmi yóò gbìn yín, n yóò yín tu nítorí èmi ọkàn padà ti ibi mo ti ṣe i yín. 11 ṣe bẹ̀ọba Babeli ̀yin ń bẹ̀, báyìí ṣe bẹ̀rẹ̀ ni Olúwa ; nítorí èmi pẹ̀yín láti pa yín mọ́ àti láti gbà yín ọwọ́ rẹ̀. 12 Èmi yóò fi àánú hàn i yín, ó ṣàánú fún un yín, ó un yín padà ilẹ̀ yín.

13 "Ṣùgbọ́n , ̀yin , Àwa gbé ilẹ̀ yìí,̀yin ti ṣe àìgbọ́ràn Olúwa Ọlọ́run yín. 14 Àti ̀yin , Bẹ́̀ kọ́, àwa yóò lọ gbé Ejibiti; níbi àwa yóò ìró ogunkógun, a yóò gbọ́ ìró fèrè, ebi oúnjẹ yóò pa , níbẹ̀ ni àwa ó máa gbé,15 nítorí náà, gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa ̀yin ìyókù Juda èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun Israẹli : ̀yin pinnu láti lọ Ejibiti láti lọ ṣe àtìpó níbẹ̀. 16 Yóò ṣe, idà ̀yin bẹ̀yóò e yín níbẹ̀; àti ìyanu náà ̀yin ń bẹ̀yóò tẹ̀yín lọ Ejibiti àti ibẹ̀ ni ̀yin yóò . 17 Nítorí náà, gbogbo àwọn ó ti pinnu láti ṣe àtìpó Ejibiti ni yóò ti ipa idà , ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn jẹ́ ẹnikẹ́ni nínú wọn tàbí àsálà nínú ibi èmi yóò sórí wọn.18 Báyìí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli : Gẹ́gẹ́ èmi ti da ìbínú àti ìrunú síta sórí àwọn ó ń gbé Jerusalẹmu, bẹ́̀ ni ìrunú mi yóò síta sórí yín, nígbà ̀yin lọ Ejibiti. ̀yin ó di ẹni ègún àti ẹni ̀gàn àti ̀sín, ̀yin yóò ibí yìí mọ́.’

19 "̀yin yòókù Juda, Olúwa ti sọ fún un yín , ṣe lọ Ejibiti.mọ èyí dájú, èmi kìlọ̀ fún un yín lónìí, 20 àṣìṣe ńlá gbá à ni ̀yin ṣe nígbà ̀yin rán mi Olúwa Ọlọ́run yín , Gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run wa fún wa; sọ fún wa gbogbo ohun ó sọ, àwa yóò ṣe é.21 Mo ti sọ fún un yín lónìí, ṣùgbọ́n síbẹ̀ ̀yin ì gbọ́ ohùn Olúwa Ọlọ́run yín, àti gbogbo ohun ó rán mi láti sọ fún un yín. 22 Ǹjẹ́ nísinsin yìí mọ èyí dájú , ̀yin yóò nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn níbikíbi ̀yin fẹ́ lọ láti ṣe àtìpó."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também