Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 10

A pa ìdílé Ahabu

1 Nísinsin yìí, Ahabu ṣì àádọ́rin ọmọkùnrin ìdílé rẹ̀ Samaria. Bẹ́̀ ni, Jehu kọ lẹ́, ó fi wọ́n ránṣẹ́ Samaria: àwọn oníṣẹ́ Jesreeli, àwọn àgbàgbà àti àwọn olùtọ́àwọn ọmọ Ahabu. Ó , 2 "kété lẹ́ti ̀dọ̀ rẹ̀, níwọ̀n ìgbà àwọn ọmọ ̀rẹ pẹ̀rẹ, ìwọ àwọn kẹ̀kẹ́ àti àwọn ẹṣin, ìlú olódi kan pẹ̀ohun ìjà, 3 yan èyí ó dára àti èyí ó níye jùlọ nínú àwọn ọmọkùnrin ̀à rẹ, o gbé e orí ìtẹ́ baba a rẹ̀. Nígbà náà, o fún ilé ̀à rẹ."

4 Ṣùgbọ́n ̀wọ́n, wọ́n , "ọba méjì le kojú ìjà i, báwo ni a ṣẹ le è ṣe é?"

5 Bẹ́̀ ẹni ń ṣe olórí ilé, ẹni ń ṣe olórí ìlú ńlá, àwọn àgbàgbà àti àwọn olùtọ́náà rán iṣẹ́ yìí Jehu, , "Ìránṣẹ́ rẹ ni àwa jẹ́ pẹ̀, àwa yóò ṣe ohunkóhun o sọ. Àwa yóò yan ẹnikẹ́ni gẹ́gẹ́ ọba; ìwọ ṣe ohunkóhun o ó dára lójú rẹ."

6 Nígbà náà ni Jehu kọ lẹ́kejì wọn, , "ìwọ ìhà tèmi, o pa ̀rọ̀ mi mọ́, orí àwọn ọmọkùnrin ̀à rẹ ̀dọ̀ mi Jesreeli ìwòyí ̀la."

Nísinsin yìí, àwọn ọmọ-aládé àádọ́rin ọkùnrin, ń bẹ pẹ̀àwọn ènìyàn ńlá ìlú náà ń tọ́ wọn. 7 Nígbà ìwé náà ̀dọ̀ wọn, àwọn ọkùnrin wọ̀nyí gbogbo àwọn ọmọ ọba gbogbo wọ́n jẹ́ àádọ́rin wọ́n pa gbogbo wọn. Wọ́n gbé orí wọn inú apẹ̀rẹ̀, wọ́n fi ránṣẹ́ Jehu Jesreeli. 8 Nígbà ìránṣẹ́ náà , ó sọ fún Jehu, "Wọ́n ti gbé orí àwọn ọmọ ọba náà ."

Nígbà náà Jehu pàṣẹ, "wọ́n òkìtì méjì àtiwọ ẹnu ibodè ìlú ńlá títí di òwúrọ̀."

9 òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, Jehu jáde lọ. Ó dúró níwájú gbogbo àwọn ènìyàn, ó , "̀yin jẹ́ aláìjẹ̀bi. Èmi ni mo dìtẹ̀ ̀mi, mo pa á, ṣùgbọ́n ta ni ó pa gbogbo àwọn wọ̀nyí? 10 Nígbà yìí, ̀rọ̀ kan Olúwa ti sọ ilé Ahabu yóò kùnà. Olúwa ti ṣe ohun ó ṣèlérí nípasẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ Elijah." 11 Bẹ́̀ ni Jehu pa gbogbo ẹni ó Jesreeli ilé Ahabu, pẹ̀lúpẹ̀gbogbo àwọn ọkùnrin ìjòyè rẹ̀, àwọn ̀rẹ́ rẹ̀ tímọ́tímọ́ àti àwọn àlùfáà rẹ̀, láì ku ẹni ó yọ nínú ewu fún un.

12 Jehu jáde lọ, ó lọ ̀kánkán Samaria. Beti-Ekedi àwọn olùṣọ́-àgùntàn. 13 Jehu pàdé díẹ̀ lára àwọn ìbátan Ahasiah ọba Juda, ó béèrè, "Ta ni ̀yin ń ṣe?"

Wọ́n , "Àwa jẹ́ ìbátan Ahasiah, àwa ti láti ìdílé ọba àti ti màmá ayaba."

14 "wọn láààyè!" ó pàṣẹ. Bẹ́̀ ni wọ́n wọn láààyè, wọ́n pa wọ́n ̀kọ̀nga Beti-Ekedi, ọkùnrin méjìlélógójì. fi ẹnìkan sílẹ̀ láìkù.

15 Nígbà a jáde níbẹ̀, ó Jehonadabu ọmọ Rekabu ń bọ̀ pàdé rẹ̀, ó súre fún un, ó fún , "Ọkàn rẹ ha ṣe déédé ọkàn mi ti ọkàn rẹ?"

Jehonadabu dáhùn , "Èmi ."

Jehu , "ó jẹ́ bẹ́̀, fún mi ọwọ́ ̀ rẹ." Bẹ́̀ ni ó ṣe pẹ̀, Jehu á lọ́wọ́ sókè sọ́dọ̀ rẹ̀ nínú kẹ̀kẹ́. 16 Jehu , "pẹ̀mi, o ìtara mi fún Olúwa." Nígbà náà ó jẹ́ ó gun kẹ̀kẹ́ rẹ̀.

17 Nígbà Jehu Samaria, ó pa gbogbo àwọn a fi kalẹ̀ ìdílé Ahabu; ó pa wọ́n run, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa a sọ Elijah.

A pa gbogbo àwọn òjíṣẹ́ Baali

18 Nígbà náà, Jehu gbogbo àwọn ènìyàn jọ, ó fún wọn , "Ahabu sin Baali díẹ̀; ṣùgbọ́n Jehu yóò sìn ín púpọ̀. 19 Nísinsin yìí, pe gbogbo àwọn wòlíì Baali jọ fún mi, gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ àti gbogbo àlùfáà rẹ̀, ṣe jẹ́ ̀kan ó , nítorí èmí yóò ẹbọ ńlá Baali. Ẹnikẹ́ni ó kọ̀ láti , láààyè mọ́." Ṣùgbọ́n Jehu fi ̀tàn ṣe é, ó pa àwọn òjíṣẹ́ Baali run.

20 Jehu , "pe àpéjọ ìwòyí ̀la fún Baali." Bẹ́̀ ni wọ́n kéde rẹ. 21 Nígbà náà, Jehu rán ̀rọ̀ káàkiri Israẹli, gbogbo àwọn òjíṣẹ́ Baali : ẹnìkan ó dúró lẹ́yìn. Wọ́n kún ilé a kọ́ fún òrìṣà títí ó fi kún láti ìkangun èkínní títí èkejì. 22 Jehu sọ fún olùṣọ́ , "ó aṣọ ìgúnwà fún gbogbo àwọn òjíṣẹ́ Baali." Bẹ́̀ ni ó aṣọ ìgúnwà jáde fún wọn.

23 Nígbà náà, Jehu àti Jehonadabu ọmọ Rekabu lọ inú ilé a kọ́ fún òrìṣà Baali. Jehu fún àwọn òjíṣẹ́ Baali , "ó yíká, o i ìránṣẹ́ Olúwa kankan pẹ̀yín níbíkìkì òjíṣẹ́ Baali." 24 Bẹ́̀ ni wọ́n wọ inú ilé lọ láti lọ ẹbọ àti ẹbọ sísun. Nísinsin yìí Jehu ti rán ọgọ́rin ọkùnrin ìta pẹ̀ìkìlọ̀ yìí: "ẹnikẹ́ni nínú yín jẹ́ ẹnikẹ́ni nínú àwọn ọkùnrin mo ń gbé ọwọ́ yín ó sálọ, yóò jẹ́ ̀yín fún ̀rẹ."

25 kété Jehu ti parí ṣíṣe ẹbọ sísun, ó pàṣẹ fún àwọn olùṣọ́ àti àwọn ìjòyè: "Wọlé lọ, o pa wọ́n, ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ó sálọ." Bẹ́̀ ni wọ́n wọn lulẹ̀ pẹ̀idà. Àwọn olùṣọ́ àti ìjòyè ju ara wọn síta, wọ́n wọ inú ojúbọ ti ilé a kọ́ fún òrìṣà Baali. 26 Wọ́n gbé òkúta bíbọ náà jáde láti inú ilé a kọ́ fún òrìṣà Baali, wọ́n o. 27 Wọ́n fọ́ òkúta bíbọ ti Baali náà túútúú, wọ́n ya ilé òrìṣà Baali bolẹ̀. Àwọn ènìyàn ń ó fún ilé ìgbẹ́ títí di ọjọ́ òní.

28 Bẹ́̀ ni Jehu pa sin Baali run Israẹli. 29 ó ti ó , Jehu yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, ó ṣokùnfà Israẹli láti ti sin ẹgbọrọ màlúù wúrà Beteli àti Dani.

30 Olúwa sọ fún Jehu , "Nítorí ìwọ ti ṣe dáradára ṣíṣe èyí ó tọ́ ojú mi, o ti ṣe ilé Ahabu gẹ́gẹ́ gbogbo èyí ó ọkàn mi, àwọn ọmọ ̀ rẹ yóò jókòó lórí ìtẹ́ Israẹli títí ìran kẹrin." 31 Síbẹ̀ Jehu ṣe pẹ̀lẹ́ láti pa òfin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli mọ́ pẹ̀tọkàntọkàn. Òun yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ Jeroboamu èyí ó ṣokùnfà Israẹli láti .

32 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Olúwa ti bẹ̀rẹ̀ dín iye Israẹli . Hasaeli fi agbára jẹ ọba lórí àwọn ọmọ Israẹli gbogbo agbègbè wọn. 33 Ìlà-oòrùn ti Jordani ni gbogbo ilẹ̀ ti Gileadi (̀kún ilẹ̀ ti ará Gadi, Reubeni, àti Manase) láti Aroeri, ó létí kòtò Arnoni láti ìhà Gileadi Baṣani.

34 Fún ti òmíràn ti iṣẹ́ ìjọba Jehu, gbogbo ohun ó ṣe, gbogbo àṣeyọrí rẹ̀, ṣé a kọ wọ́n inú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli?

35 Jehu sinmi pẹ̀baba a rẹ̀, a sin ín Samaria Jehoahasi ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba. 36 Àkókò Jehu fi jẹ ọba lórí Israẹli Samaria jẹ́ ọdún méjìdínlọ́gbọ̀n.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também