Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 19

Àsọtẹ́lẹ̀ nípa ìgbàlà Jerusalẹmu

1 Nígbà ọba Hesekiah gbọ́ èyí, ó fa aṣọ rẹ̀ ya ó wọ aṣọ ̀fọ̀ ó lọ àgọ́ Olúwa 2 Ó rán Eliakimu olùtọ́ààfin, Ṣebna akọ̀àti olórí àlùfáà gbogbo wọn wọ aṣọ ̀fọ̀, ̀dọ̀ wòlíì Isaiah ọmọ Amosi. 3 Wọ́n sọ fún ún , "Èyí ni ohun Hesekiah sọ: ọjọ́ òní jẹ́ ọjọ́ ìpọ́njú àti ìbáwí àti ̀gàn, gẹ́gẹ́ ìgbà ọmọdé ojú ìbímọ agbára láti fi wọn. 4 Ó jẹ́ Olúwa Ọlọ́run yóò gbọ́ gbogbo ̀rọ̀ olùdarí pápá, ẹni ̀rẹ̀, ọba Asiria, ti rán láti fi Ọlọ́run alààyè ṣẹ̀sín, yóò a fún ̀rọ̀ ti Olúwa Ọlọ́run rẹ ti gbọ́. Nítorí náà gbàdúrà fún ìyókù àwọn ó láààyè."

5 Nígbà ìránṣẹ́ ọba Hesekiah lọ ̀dọ̀ Isaiah, 6 Isaiah fún wọn , "Sọ fún ̀rẹ, Èyí ni ohun Olúwa sọ : ṣe bẹ̀ohun ̀yin ti gbọ́—àwọn ̀rọ̀ ìhàlẹ̀ pẹ̀èyí ti ọba Asiria ti sọ̀rọ̀-òdì mi. 7 Gbọ́! Èmi yóò rán ̀kan sínú rẹ̀ nígbà ó gbọ́ ariwo, yóò padà ìlú rẹ̀, níbẹ̀ ni èmi yóò gbé e lulẹ̀ pẹ̀idà.’ "

8 Nígbà olùdarí pápá gbọ́ ọba Asiria ti kúrò Lakiṣi ó padà ó ọba níbi ti ó gbé ń Libina .

9 Nísinsin yìí, Sennakeribu gbọ́ ìròyìn Tirakah, ọba Etiopia ti Ejibiti ó ń yan jáde lọ láti lọ a jagun. Bẹ́̀ ni ó tún rán oníṣẹ́ Hesekiah pẹ̀̀rọ̀ yìí , 10 "Sọ fún Hesekiah ọba Juda , ṣe jẹ́ òrìṣà ìwọ gbẹ́kẹ̀ó tàn ó jẹ nígbà ó , Jerusalẹmu a fi ọwọ́ ọba Asiria.11 Lóòótọ́ ìwọ ti gbọ́ gbogbo ohun ọba Asiria ó ṣe gbogbo àwọn ìlú, ó pa wọ́n run pátápátá. Ìwọ yóò gbàlà? 12 Ṣé àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè a ti parun láti ̀dọ̀ àwọn baba ńlá mi gbà wọ́n : òrìṣà Gosani, Harani Reṣefu àti gbogbo ènìyàn Edeni wọ́n Teli-Assari? 13 Níbo ni ọba Hamati wa, ọba Arpadi, ọba ìlú Sefarfaimi, ti Hena, tàbí ti Iffa gbé ?"

Àdúrà Hesekiah

14 Hesekiah gba lẹ́láti ̀dọ̀ ìránṣẹ́ ó á. Nígbà náà ó lọ òkè ilé a kọ́ fún Olúwa ó tẹ́ síwájú Olúwa. 15 Hesekiah gbàdúrà Olúwa: "Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ń gbé àárín àwọn kérúbù, ìwọ nìkan ni Ọlọ́run lórí gbogbo ìjọba ó láyé, ìwọ ti ̀run àti ayé. 16 Dẹtí sílẹ̀, Olúwa o gbọ́; la ojú rẹ, Olúwa, o i, gbọ́ ̀rọ̀ Sennakeribu ó rán láti fi Ọlọ́run alààyè.

17 "Òtítọ́ ni, Olúwa, ọba Asiria ti pa orílẹ̀-èdè wọ̀nyí run àti ilẹ̀ wọn. 18 Wọ́n ti ju òrìṣà wọn sínú iná wọn ti wọ́n jẹ́, nítorí wọn í ṣe ọlọ́run. Ṣùgbọ́n, wọ́n jẹ́ igi àti òkúta a ṣe lọ́ṣọ̀́ pẹ̀ọwọ́ ènìyàn. 19 Nísinsin yìí Olúwa Ọlọ́run wa, gbà kúrò lọ́wọ́ rẹ̀, bẹ́̀ ni gbogbo àwọn ìjọba lórí ilẹ̀ ayé le mọ̀ ìwọ nìkan ṣoṣo ni, Olúwa Ọlọ́run wa."

Isaiah sọtẹ́lẹ̀ nípa ìṣubú Sennakeribu

20 Nígbà náà Isaiah ọmọ Amosi rán oníṣẹ́ Hesekiah , "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ: Mo ti gbọ́ àdúrà rẹ nípa ti Sennakeribu ọba Asiria. 21 Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa ti sọ nípa rẹ̀,

" Wúńdíá ọmọbìnrin Sioni

kẹ́gàn rẹ ó fi ́ ṣe ẹlẹ́.

Ọmọbìnrin Jerusalẹmu

mi orí gẹ́gẹ́ o ti sálọ.

22 Ta ni ìwọ ti o kẹ́gàn rẹ̀?

Lórí ta ni ìwọ ti gbé ohùn rẹ

sókè ó gbé ojú sókè ìgbéraga?

Lórí ẹni mímọ́ ti Israẹli!

23 Nípa àwọn ìránṣẹ́ rẹ

ìwọ ti sọ̀rọ̀ búburú Olúwa.

wọ ,

"Pẹ̀̀pọ̀ kẹ̀kẹ́ mi

ni èmi fi orí àwọn òkè ńlá,

ibi gíga jùlọ Lebanoni.

Èmi a igi kedari gíga rẹ̀ lulẹ̀,

àti ààyò igi firi rẹ̀.

Èmi a lọ orí òkè ìbùwọ̀ rẹ̀

sínú ibi ó dára nínú igbó rẹ̀.

24 Mo ti gbẹ́ kànga ilẹ̀ àjèjì,

mo mu omi níbẹ̀.

Pẹ̀àtẹ́lẹsẹ̀ mi,

èmi ti gbẹ́ gbogbo omi odò ó Ejibiti."

25 " Ṣé ìwọ ì gbọ́?

ọjọ́ pípẹ́ sẹ́yìn mo yàn án.

ọjọ́ ogbó ni mo ṣètò rẹ̀;

nísinsin yìí mo ti ìkọjá

ìwọ ti ìlú olódi padà

òkìtì àlàpà òkúta.

26 Àwọn ènìyàn wọn ń gbẹ nípa,

wọ́n ti á láàmú

wọ́n ti ṣọ́ di ìtìjú.

Wọ́n dàbí koríko igbó lórí pápá,

gẹ́gẹ́ ọkà ó rẹ̀ dànù ó dàgbàsókè,

gẹ́gẹ́ fífún ọkà ó jáde.

27 " Ṣùgbọ́n èmi mọ ibi ìwọ

dúró àti ìgbà ìwọ tàbí

lọ àti ìwọ ṣe ìkáàánú rẹ: mi.

28 Ṣùgbọ́n ìkáàánú rẹ mi

àti ìrora rẹ etí mi,

Èmi yóò gbé ìwọ̀ mi imú rẹ

àti ìjánu mi ẹnu rẹ,

èmi yóò padà

nípa wíwá rẹ.

29 "Èyí yóò jẹ́ àmì fún , ìwọ Hesekiah:

"Ọdún yìí ìwọ yóò jẹ ohun ó fún rara rẹ̀,

àti ọdún kejì ohun ó jáde láti inú ìyẹn.

Ṣùgbọ́n ọdún kẹta, gbìn o kórè,

gbin ọgbà àjàrà o jẹ èso rẹ̀.

30 Lẹ́̀kan i ìyókù ti ilé Juda

yóò tún hu gbòǹgbò lábẹ́, yóò so èso lókè.

31 Láti inú Jerusalẹmu àwọn ìyókù yóò ti

àti láti orí òkè Sioni ni ̀pọ̀ àwọn ó àsálà.

Ìtara Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò ṣe èyí.

32 "Nítorí èyí ni ohun Olúwa sọ nípa ti ọba Asiria:

"wọ ìlú yìí

tàbí ta ọfà síbí.

níwájú rẹ pẹ̀

àpáta tàbí ìdọ̀àgbò ̀kánkán rẹ.

33 Nípa ̀ó gbà ni yóò padà;

yóò wọ ìlú ńlá yìí,

ni Olúwa .

34 Èmi yóò ààbò bo ìlú ńlá yìí,

èmi yóò pa á mọ́ fún èmi tìkára mi àti fún Dafidi ìránṣẹ́ mi."

35 alẹ́ ọjọ́ náà, angẹli Olúwa jáde lọ ó pa ̀kẹ́ mẹ́sàn-án ẹgbẹ̀́dọ́gbọ̀n (185,000) ènìyàn ibùdó àwọn ará Asiria. Nígbà wọ́n dìde dúró òwúrọ̀ ọjọ́ kejì níbẹ̀ ni gbogbo òkú ! 36 Bẹ́̀ ni Sennakeribu ọba Asiria wọ àgọ́ ó padà, ó padà Ninefe ó dúró níbẹ̀.

37 ọjọ́ kan, nígbà ó sùn nínú ilé òrìṣà Nisroki, ọmọkùnrin rẹ̀ Adrameleki àti Ṣareseri e lulẹ̀ pẹ̀idà, wọ́n sálọ ilẹ̀ Ararati Esarhadoni ọmọkùnrin rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também