Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 8

Obìnrin ará Ṣunemu gba ilẹ̀ rẹ̀ padà

1 Nísinsin yìí, Eliṣa fún obìnrin náà ọmọ rẹ̀ ọkùnrin padà sáyé , "Jáde lọ pẹ̀ìdílé rẹ o lọ dúró fún ìgbà díẹ̀ ibikíbi o le dúró , nítorí Olúwa ti pàṣẹ ìyàn ìlú yóò ọdún méje." 2 Obìnrin náà tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ ènìyàn Ọlọ́run ti sọ. Òun àti ìdílé rẹ̀ lọ, wọ́n ṣe àtìpó ilẹ̀ àwọn ará Filistini fún ọdún méje.

3 ̀yìn ọdún méje ó padà láti ilẹ̀ àwọn ará Filistini ó lọ ̀dọ̀ ọba láti lọ bẹ̀ ́ fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀. 4 Ọba ń sọ̀rọ̀ Gehasi, ìránṣẹ́ ènìyàn Ọlọ́run , "Sọ fún mi nípa gbogbo ohun ńlá Eliṣa ti ṣe." 5 Gehasi ti ń sọ Eliṣa ṣe òkú di alààyè, obìnrin náà ọmọ rẹ̀ ọkùnrin Eliṣa ti padà ayé láti bẹ ọba fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀.

Gehasi , "Obìnrin náà nìyìí olúwa mi ọba, ọmọkùnrin rẹ náà nìyí Eliṣa ti dìde ayé." 6 Ọba béèrè lọ́wọ́ obìnrin náà nípa rẹ̀, ó sọ fún un.

Ó yan ìjòyè kan fún ún fún ̀rọ̀ rẹ̀ ó fún un , "fún un padà gbogbo ohun ó jẹ́ tirẹ̀, àti pẹ̀gbogbo èrè ilé rẹ̀ fún ún láti ọjọ́ ó ti kúrò ìlú títí di àsìkò yìí."

Hasaeli pa Beni-Hadadi

7 Eliṣa lọ Damasku, Beni-Hadadi ọba Siria ń ṣe àìsàn. Nígbà wọ́n sọ fún ọba , "Ènìyàn Ọlọ́run ti láti gbogbo ̀òkè síbí," 8 ọba fún Hasaeli , "ọrẹ lọ́wọ́ rẹ, lọ pàdé ènìyàn Ọlọ́run. o béèrè Olúwa láti ̀dọ̀ rẹ̀, béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn yìí?"

9 Hasaeli lọ láti pàdé Eliṣa, ó lọ pẹ̀rẹ̀ ̀bùn gẹ́gẹ́ ogójì ẹrù ìbákasẹ gbogbo ìní ó dára fún wíwò ti Damasku, ó wọlé lọ ó dúró níwájú rẹ̀, ó , "Ọmọ rẹ Beni-Hadadi ọba Siria rán mi láti béèrè , Ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn mi yìí?’ "

10 Eliṣa da á lóhùn , "Lọ o lọ sọ fún un , Ìwo ìbá sàn nítòótọ́’; ṣùgbọ́n Olúwa ti fihàn nítòótọ́ òun yóò kùú." 11 Ó ranjú mọ́ ọn pẹ̀àtẹjúmọ́ gidigidi títí ojú fi ti Hasaeli. Nígbà náà ènìyàn Ọlọ́run bẹ̀rẹ̀ sọkún.

12 "ni ó olúwa mi fi ń sọkún?" Hasaeli béèrè.

"Nítorí èmi mọ ibi ìwọ yóò ṣe Israẹli," ó dáhùn , "Ìwọ yóò fi iná si odi agbára wọn, ìwọ yóò, pa àwọn ̀dọ́ ọmọkùnrin wọn pẹ̀idà, ìwọ yóò kọlù àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn, ìwọ ó fọ́ wọn túútúú, ìwọ o la inú àwọn aboyún wọn."

13 Hasaeli . "Báwo ni ìránṣẹ́ rẹ, ajá lásán làsàn yóò ṣe ṣe irú nǹkan ńlá bẹ́̀?"

"Olúwa ti fihàn ìwọ ni yóò jẹ ọba Siria," Eliṣa a lóhùn.

14 Nígbà náà Hasaeli fi Eliṣa sílẹ̀ ó padà ̀dọ̀ ̀rẹ̀. Nígbà Beni-Hadadi béèrè, "ni ohun Eliṣa sọ fún ?" Hasaeli a lóhùn, "Ó sọ fún mi ìwọ yóò sàn nítòótọ́." 15 Ṣùgbọ́n ọjọ́ kejì ó aṣọ ó nípọn, ó í bọ inú omi ó tẹ̀ ́ ojú ọba, bẹ́̀ ni ó . Nígbà náà Hasaeli rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Jehoramu ọba Juda

16 ọdún karùn-ún ti Joramu ọmọ Ahabu ọba Israẹli, nígbà Jehoṣafati jẹ́ ọba Juda, Jehoramu ọmọ Jehoṣafati bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba Juda. 17 Ó jẹ́ ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n nígbà ó di ọba. Ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́jọ. 18 Ó rìn ̀ọba Israẹli, gẹ́gẹ́ ilé Ahabu ti lọ, nítorí ó fẹ́ ọmọbìnrin Ahabu ó ṣe ohun búburú níwájú Olúwa. 19 ó tilẹ̀ jẹ́ , nítorí ti ìránṣẹ́ rẹ̀ Dafidi. Olúwa fẹ́ pa Juda run, ó ti ṣèlérí láti ṣètọ́ìmọ́lẹ̀ fún Dafidi àti àwọn ilé rẹ̀ títí láéláé.

20 àkókò Jehoramu, Edomu ṣọ̀tẹ̀ Juda, wọ́n gbé ọba tiwọn kalẹ̀. 21 Bẹ́̀ ni Jehoramu lọ Sairi pẹ̀gbogbo kẹ̀kẹ́ rẹ̀. Àwọn ará Edomu i àti kẹ̀kẹ́ àwọn olórí wọn, ṣùgbọ́n ó dìde dúró òru; àwọn ogun rẹ̀ síbẹ̀síbẹ̀, padà lọ ilé. 22 Títí ó fi di òní, Edomu nínú ̀tẹ̀ lórí Juda, Libina ṣọ̀tẹ̀ àkókò kan náà.

23 Gẹ́gẹ́ fún iṣẹ́ mìíràn ti ìjọba Jehoramu, àti gbogbo ohun ó ṣe, ṣé a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda? 24 Jehoramu sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀ a sin ín pẹ̀wọn ìlú Dafidi, Ahasiah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Ahasiah ọba Juda

25 ọdún méjìlá Joramu ọmọkùnrin Ahabu ọba Israẹli, Ahasiah ọmọkùnrin Jehoramu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀. 26 Ahasiah jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà ó di ọba. Ó jẹ ọba ọdún kan Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Ataliah, ọmọbìnrin Omri ọba Israẹli. 27 Nígbà ó rin ̀ilé Ahabu ó ṣe búburú níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ ilé Ahabu ti ṣe, nítorí ó tan nípa ìgbéyàwó ìdílé Ahabu.

28 Ahasiah lọ pẹ̀Joramu ọmọ Ahabu lọ ogun lórí Hasaeli ọba Aramu Ramoti Gileadi. Àwọn ará Siria ṣẹ́ Joramu lẹ́sẹ̀. 29 Bẹ́̀ ni ọba Joramu padà Jesreeli láti wo ọgbẹ́ rẹ̀ sàn ará Siria ti jẹ lórí rẹ̀ Ramoti ojú ogun rẹ̀ pẹ̀Hasaeli ọba Aramu.

Nígbà náà Ahasiah ọmọ Jehoramu ọba Juda sọ̀kalẹ̀ lọ Jesreeli láti lọ wo Joramu ọmọ Ahabu nítorí ó fi ara pa.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também