Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kọrinti 4

Àwọn aposteli Kristi

1 4.1: 1Kọ 9.17; Ro 11.25; 16.25. Nítorí náà, ṣe yẹ ènìyàn máa gẹ́gẹ́ ìránṣẹ́ àti ìríjú a fún ni oore-ọ̀fẹ́ láti mọ Kristi a fún oore-ọ̀fẹ́ láti mọ àwọn ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run. 2 Òun kan náà ó tọ́ fún ìríjú, ni ó jẹ́ olóòtítọ́. 3 Ṣùgbọ́n ohun kíkíní ni fún mi , máa ṣe ìdájọ́ mi, tàbí a máa ṣe ìdájọ́ nípa ìdájọ́ ènìyàn; nítòótọ́, èmi tilẹ̀ ara mi lẹ́jọ́. 4 4.4: 2Kọ 1.12.Nítorí ̀ọkàn mi mi ̀bi; ṣùgbọ́n a ti ipa èyí mi láre, ṣùgbọ́n Olúwa ni ẹni ń ṣe ìdájọ́ mi. 5 4.5: Ro 2.16; 1Kọ 3.13; 2Kọ 10.18; Ro 2.29.Nítorí náà, ṣe ṣe ìdájọ́ ohunkóhun, Olúwa padà , ẹni yóò ohunkóhun ó fi ara sin ìmọ́lẹ̀, yóò fi ìmọ̀ ọkàn ènìyàn hàn, nígbà náà ni olúkúlùkù yóò ìyìn tirẹ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run.

6 4.6: 1Kọ 1.19,31; 3.19-20; 1.12; 3.4. kíyèsi i , mo ti fi ara mi àti Apollo ṣe àpẹẹrẹ nǹkan mo , ̀yin ti ipa wa kọ́ láti máa ṣe ohun a ti kọ̀kọjá. "ẹnikẹ́ni nínú yín ṣe tìtorí ẹnìkan gbéraga ẹnìkejì." 7 Nítorí ta ni ó yàtọ̀ àwọn ẹlòmíràn? ni ìwọ ni ìwọ gbà? ìwọ ba gbà á, èétiṣe ìwọ fi ń halẹ̀ ẹni ìwọ gba á?

8 Ni báyìí ohun gbogbo ń fẹ́! Báyìí ti di ọlọ́rọ̀! ti di ọba. Lójú yín, àwa ti di ẹni ̀yìn. Ìbá dùn mọ́ mi ó jẹ́ lóòtítọ́ ni ti di ọba lórí ìtẹ́ yín: a ó máa jẹ ọba pẹ̀yín! 9 4.9: 1Kọ 15.31; 2Kọ 11.23; Ro 8.36; Hb 10.33.Nítorí mo Ọlọ́run ń fi àwa aposteli hàn ìkẹyìn ẹni a lẹ́bi ikú àwọn, nítorí a fi ṣe ìran fún àwọn ènìyàn àti àwọn angẹli àti gbogbo ayé. 10 4.10: 1Kọ 1.18; 2Kọ 11.19; 1Kọ 3.18; 2Kọ 13.9; 1Kọ 2.3.Àwa jẹ́ aṣiwèrè nítorí Kristi, ṣùgbọ́n ̀yin jẹ́ ọlọ́gbọ́n nínú Kristi! Àwa jẹ́ aláìlera, ṣùgbọ́n ̀yin jẹ́ alágbára! ̀yin jẹ́ ẹni àyẹ́, àwa jẹ ẹni ̀gàn! 11 4.11: Ro 8.35; 2Kọ 11.23-27.Títí di wákàtí yìí ni a ń rìn kiri nínú ebi àti òǹgbẹ, a n wọ aṣọ àkísà, a ń wa, a ibùgbé kan. 12 4.12: Ap 18.3; 1Pt 3.9.a ń fi ọwọ́ ara wa ṣiṣẹ́, wọn ń gàn wa, àwa ń súre, wọn ń ṣe inúnibíni wa, àwa ń forítì i. 13 Wọn ń kẹ́gàn wa, àwa ń bẹ̀bẹ̀. Títí di ìsinsin yìí ni a ti ohun ̀gbin ayé, orí àkìtàn gbogbo ayé.

14 Èmi kọ̀nǹkan wọ̀nyí láti fi dójútì yín, ṣùgbọ́n láti kìlọ̀ fún un yín àwọn ọmọ mi mo yàn fẹ́. 15 4.15: 1Kọ 1.30; Fm 10.Nítorí ̀yin tilẹ̀ ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) olùkọ́ni nínú Kristi, ṣùgbọ́n ̀yin ni baba púpọ̀; nítorí nínú Kristi Jesu ni mo jẹ́ baba fún un yín nípasẹ̀ ìyìnrere. 16 Nítorí náà mo bẹ̀ yín, máa ṣe àfarawé mi. 17 4.17: 1Kọ 16.10; Ap 16.1; 1Kọ 7.17.Nítorí náà ni mo ṣe rán Timotiu i yín, ẹni í ṣe ọmọ mi olùfẹ́ àti olódodo nínú Olúwa, ẹni yóò máa yín rántí ̀mi ó nínú Kristi Jesu, gẹ́gẹ́ mo ti ń kọ́ni nínú gbogbo ìjọ níbi gbogbo.

18 Mo mọ̀ àwọn mìíràn nínú yín ya onígbèéraga ènìyàn, wọn ń ̀ń mi láti sọ́dọ̀ yín. 19 Ṣùgbọ́n èmi yóò tọ̀ yín àìpẹ́ yìí Olúwa fẹ́; èmi yóò ṣe ìwádìí àwọn agbéraga yìí ṣe ń sọ̀rọ̀ àti agbára wọ́n . 20 Nítorí ìjọba Ọlọ́run í ṣe nínú ̀rọ̀, ṣe nínú agbára. 21 4.21: 2Kọ 1.23.Èwo ni yàn? ń sọ́dọ̀ yín pẹ̀pàṣán, tàbí ni ìfẹ́, àti ̀tútù?

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também