Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 2

Elijah gun kẹ̀kẹ́ iná lọ ̀run

1 Nígbà Olúwa ń fẹ́ gbé Elijah lọ òkè ̀run nínú àjà, Elijah àti Eliṣa ̀láti Gilgali. 2 Elijah fún Eliṣa , "Dúró níbí; Olúwa rán mi lọ Beteli."

Ṣùgbọ́n Eliṣa , "Gẹ́gẹ́ ó ti dájú Olúwa láyé àti gẹ́gẹ́ ó ti yẹ, èmi fi ́ sílẹ̀." Bẹ́̀ ni wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ Beteli.

3 Àwọn ọmọ wòlíì Beteli jáde ̀dọ̀ Eliṣa wọ́n béèrè , "Ṣé ìwọ mọ̀ Olúwa yóò gba ̀rẹ kúrò lọ́dọ̀ rẹ lónìí?"

"Bẹ́̀ ni, èmi mọ̀," Eliṣa dáhùn, "Ṣùgbọ́n ṣe sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀."

4 Nígbà náà Elijah fún un , "Dúró níbí, Eliṣa: Olúwa ti rán mi lọ Jeriko."

Ó a lóhùn , "ó ti dájú Olúwa àti ìwọ náà , èmi fi ́ sílẹ̀." Wọ́n jọ lọ Jeriko.

5 Àwọn ọmọ wòlíì ó Jeriko gòkè tọ Eliṣa wọ́n béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Ṣé ìwọ mọ̀ Olúwa yóò gba ̀rẹ kúrò lọ́dọ̀ rẹ lónìí?"

"Bẹ́̀ ni, èmi mọ̀," Ó wọn lóhùn, "Ṣùgbọ́n ṣe sọ nípa rẹ̀."

6 Nígbà náà Elijah fún un , "Dúró níbí; Olúwa rán mi lọ Jordani."

Ó a lóhùn , "Gẹ́gẹ́ ó ti jẹ́ , Olúwa àti gẹ́gẹ́ o ti , èmi fi ́ sílẹ̀." Bẹ́̀ ni àwọn méjèèjì jọ ń lọ.

7 Àádọ́ta àwọn ọkùnrin ọmọ wòlíì lọ láti lọ dúró ̀jíjìn, wọ́n kọ ojú da ibi Elijah àti Eliṣa ti dúró Jordani. 8 Elijah agbádá ó a sókè ó lu omi náà pẹ̀rẹ̀. Omi náà pín ̀tún àti òsì, àwọn méjèèjì rékọjá lórí ilẹ̀ gbígbẹ.

9 Nígbà wọ́n rékọjá, Elijah fún Eliṣa , "Sọ fún mi, ni èmi ṣe fún ó di wọ́n gbà kúrò lọ́dọ̀ rẹ?"

"Jẹ́ èmi ó jogún ìlọ́po méjì ̀rẹ." Ó a lóhùn.

10 "Ìwọ ti béèrè ohun ó ṣòro," Elijah , "Síbẹ̀ ìwọ mi nígbà a gbà kúrò lọ́wọ́ rẹ, yóò jẹ́ tìrẹ bẹ́̀ kọ́ bẹ́̀."

11 2.11: If 11.12. Gẹ́gẹ́ wọ́n ti ń rìn lọ wọ́n ń sọ̀rọ̀ pọ̀, lọ́gán kẹ̀kẹ́ iná àti ẹṣin iná yọ wọn ó ya àwọn méjèèjì nípa, Elijah gòkè lọ ̀run pẹ̀àjà. 12 Eliṣa èyí ó kígbe sókè, "Baba mi! Baba mi! Kẹ̀kẹ́ àti ẹlẹ́ṣin Israẹli!" Eliṣa i mọ́. Ó aṣọ ara rẹ̀ ó wọ́n ya sọ́tọ̀.

13 Ó agbádá ó ti jábọ́ láti ̀dọ̀ Elijah ó padà lọ, ó dúró lórí bèbè Jordani. 14 Ó agbádá náà ó jábọ́ láti ọwọ́ rẹ̀, ó lu omi pẹ̀rẹ̀. "Níbo ni Olúwa Ọlọ́run Elijah ?" Ó béèrè. Nígbà ó lu omi náà, ó pín apá ̀tún àti òsì, Eliṣa rékọjá.

15 Àwọn ọmọ wòlíì láti Jeriko, wọ́n ń , , "̀Elijah sinmi Eliṣa." Wọ́n lọ láti lọ a, wọ́n dojúbolẹ̀ níwájú rẹ̀. 16 "ó," wọ́n , "Àwa ìránṣẹ́ ni àádọ́ta ọkùnrin alágbára. Jẹ́ wọ́n lọ láti lọ ̀rẹ . Bóyá ̀Olúwa ti gbé e sókè, ó gbé e kalẹ̀ lórí òkè ńlá tàbí lórí ilẹ̀."

"Rárá," Eliṣa a lóhùn , "ṣe rán wọn."

17 Ṣùgbọ́n wọ́n rọ̀ ́ títí ojú fi í láti gbà. Ó , "Rán wọn." Wọ́n rán àádọ́ta ènìyàn ó a fún ọjọ́ mẹ́ta ṣùgbọ́n wọn i. 18 Nígbà wọ́n padà ̀dọ̀ Eliṣa, ó dúró Jeriko, ó fún wọn , "Ṣé èmi sọ fún un yín lọ?"

Ìwòsàn omi

19 Àwọn ọkùnrin ìlú fún Eliṣa, , "ó, olúwa wa, ìtẹ̀ìlú yìí dára, gẹ́gẹ́ ti i, ṣùgbọ́n omi náà burú, ilẹ̀ náà ."

20 Ó , "àwokòtò tuntun fún mi , o iyọ̀ inú rẹ̀." Wọ́n gbé e fún un.

21 Nígbà náà ó jáde lọ ibi orísun omi, ó da iyọ̀ inú rẹ̀, ó , "Èyí ni ohun Olúwa : Èmi ti wo omi yìí sàn. ikú mọ́ tàbí ilẹ̀ náà .’ " 22 Omi náà ti dára ni mímu títí di òní, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Eliṣa ti sọ.

Wọ́n fi Eliṣa ṣe yẹ̀yẹ́

23 Láti ibẹ̀ Eliṣa lọ sókè Beteli gẹ́gẹ́ ó ti ń rìn lọ lójú ̀, àwọn ̀dọ́ kan jáde láti ìlú náà wọ́n fi ṣe ẹlẹ́. "Máa lọ sókè ìwọ apárí!" Wọ́n . "Máa lọ sókè ìwọ apárí!" 24 Ó yípadà, ó wọ́n ó fi wọ́n orúkọ Olúwa. Nígbà náà beari méjì jáde láti inú igbó ó lu méjìlélógójì lára àwọn ̀dọ́ náà. 25 Ó lọ orí òkè Karmeli láti ibẹ̀ ó padà Samaria.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também