Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 18

Hesekiah ọba Juda

1 18.1-3: 2Ki 29.1,2. ọdún kẹta Hosea ọmọ Ela ọba Israẹli, Hesekiah ọmọ Ahasi ọba Juda bẹ̀rẹ̀ ìjọba. 2 Ó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́̀́dọ́gbọ̀n nígbà ó ti di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Abijah ọmọbìnrin Sekariah. 3 Ó ṣe ohun ó dára níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ i baba rẹ̀ Dafidi ti ṣe. 4 Ó ibi gíga náà kúrò, ó fọ́ àwọn ère òkúta, ó àwọn ère Aṣerah lulẹ̀, ó fọ́ ejò idẹ Mose ti ṣe náà túútúú, títí di ọjọ́ àwọn ọmọ Israẹli ń sun tùràrí . (Wọ́n é Nehuṣitani.)

5 Hesekiah gbẹ́kẹ̀Olúwa Ọlọ́run Israẹli. ṣí ẹnìkan ó dàbí tirẹ̀ lára gbogbo àwọn ọba Juda, bóyá ó jẹ tàbí lẹ́yìn rẹ̀. 6 Ó súnmọ́ Olúwa, dẹ́kun láti í lẹ́yìn: ó pa òfin Olúwa mọ́ ó ti fi fún Mose. 7 Olúwa pẹ̀rẹ̀; ó ń ṣe rere nínú gbogbo ohun ó dáwọ́. Ó ṣe ̀tẹ̀ ọba Asiria sìn ín. 8 Láti ilé ìṣọ́ títí ìlú olódi, ó pa àwọn ará Filistini run, àti títí Gasa àti agbègbè rẹ̀.

9 ọdún kẹrin ọba Hesekiah, nígbà ó jẹ́ ọdún keje Hosea ọmọ Ela ọba Israẹli. Ṣalamaneseri ọba Asiria yàn lára Samaria ó tẹ̀í. 10 Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta Asiria gbé e. Bẹ́̀ ni wọ́n Samaria ọdún kẹfà Hesekiah ó jẹ́ ọdún kẹsànán Hosea ọba Israẹli. 11 Ọba Asiria Israẹli kúrò Asiria, wọ́n ṣe àtìpó wọn Hala, Gosani létí odò Habori àti ìlú àwọn ará Media. 12 Èyí ṣẹlẹ̀ nítorí wọn pa àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wọn mọ́. Ṣùgbọ́n wọ́n ti májẹ̀rẹ̀ gbogbo èyí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti pàṣẹ. Wọn fi etí wọn sílẹ̀ òfin wọn gbé wọn jáde.

13 ọdún kẹrìnlá Hesekiah jẹ ọba, Sennakeribu ọba Asiria kọlu gbogbo ìlú olódi ti Juda ó pa wọ́n run. 14 Bẹ́̀ ni Hesekiah ọba Juda ránṣẹ́ yìí ọba Asiria Lakiṣi, , "Mo ti ṣẹ̀, padà lẹ́yìn mi: èmi yóò san ohunkóhun ìwọ béèrè lọ́wọ́ mi." Ọba Asiria bu fún Hesekiah ọba Juda ̀́dúnrún (300) tálẹ́ǹtì fàdákà àti ọgbọ̀n tálẹ́ǹtì wúrà. 15 Hesekiah fún un gbogbo fàdákà a nínú ilé Olúwa àti nínú ìṣúra ilé ọba.

16 àkókò yìí Hesekiah ọba Juda wúrà ó ẹnu ìlẹ̀kùn ilé Olúwa, kúrò àti ti òpó Hesekiah ọba Juda ti gbéró ó fi fún ọba Asiria.

Sennakeribu halẹ̀ mọ́ Jerusalẹmu

17 Ọba Asiria rán alákòóso gíga jùlọ, ìjòyè pàtàkì àti àwọn adarí pápá pẹ̀àwọn ọmọ-ogun ó pọ̀, láti Lakiṣi ọba Hesekiah Jerusalẹmu. Wọ́n òkè Jerusalẹmu wọ́n dúró etí ìdarí omi àbàtà òkè, ojú ̀lọ òpópó pápá alágbàfọ̀. 18 Wọ́n pe ọba; àti Eliakimu ọmọ Hilkiah ẹni í ṣe ilé olùtọ́, Ṣebna akọ̀, àti Joah ọmọkùnrin Asafu ó jẹ́ akọ̀ìrántí jáde pẹ̀wọn.

19 Olùdarí pápá fún wọn , "Sọ fún Hesekiah ,

" Èyí ni ohun ọba ńlá, ọba Asiria sọ: ni ìgbẹ́kẹ̀yìí ìwọ gbẹ́kẹ̀? 20 Ìwọ ìwọ ni ìmọ̀ àti agbára láti jagun, ṣùgbọ́n ìwọ sọ̀rọ̀ òfìfo lásán. Ǹjẹ́ ta ni ìwọ gbẹ́kẹ̀ rẹ , ìwọ fi ń ṣe ̀tẹ̀ mi? 21 ó, nísinsin yìí, ìwọ gbẹ́kẹ̀ rẹ Ejibiti, ̀rún ̀pẹlẹbẹ ìyè fífọ́ yìí, èyí yóò wọ inú ọwọ́ ẹni ó fi ara í. Bẹ́̀ ni Farao ọba Ejibiti ṣe fún gbogbo àwọn ó gbẹ́kẹ̀ wọn e. 22 ìwọ sọ fún mi , "Àwa gbẹ́kẹ̀ wa Olúwa Ọlọ́run." Òun ha kọ́ ẹnìkan náà ibi gíga àti àwọn pẹpẹ Hesekiah kúrò, ó fún Juda àti Jerusalẹmu , "O gbọdọ̀ sìn níwájú pẹpẹ yìí Jerusalẹmu"?

23 " nísinsin yìí, ṣe àdéhùn pẹ̀̀mi, ọba Asiria èmi yóò fún ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) ẹṣin ìwọ àwọn yóò gùn ún orí rẹ! 24 Báwo ni ìwọ yóò ha ti ṣe le ojú balógun kan ó kéré jùlọ padà nínú àwọn ìránṣẹ́ olúwa mi, ìwọ gbẹ́kẹ̀ rẹ Ejibiti fún àwọn kẹ̀kẹ́ àti ẹlẹ́ṣin? 25 Síwájú i, èmi ti láti àti láti parun ibí yìí láìsí ̀rọ̀ láti ̀dọ̀ Olúwa? Olúwa fún rara rẹ̀ sọ fún mi n yára láti yan lórí ìlú yìí, n pa á run.’ "

26 Nígbà náà Eliakimu ọmọ Hilkiah, àti Ṣebna àti Joah sọ fún olùdarí pápá , "Jọ̀wọ́ sọ̀rọ̀ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ èdè Aramaiki, nítorí ti ó wa, ṣe sọ̀rọ̀ fún wa pẹ̀èdè Heberu etí ìgbọ́ àwọn ènìyàn ń bẹ lórí odi."

27 Ṣùgbọ́n aláṣẹ dáhùn , "Ṣé fún ̀rẹ àti ìwọ nìkan ̀mi rán mi láti sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí í í ṣe fún àwọn ọkùnrin ó jókòó lórí odi ni gẹ́gẹ́ ìwọ, ni yóò láti jẹ ìgbẹ́ ará wọn wọ́n mu ìtọ̀ ará wọn?"

28 Nígbà náà, aláṣẹ dìde, ó jáde èdè Heberu , "gbọ́ ̀rọ̀ ọba ńlá, ọba Asiria! 29 Èyí ni ohun ọba sọ, ṣe jẹ́ Hesekiah tàn ́ jẹ le gbà ́ kúrò ọwọ́ mi. 30 ṣe jẹ́ Hesekiah yín gbẹ́kẹ̀Olúwa nípa sísọ , Olúwa yóò gbà nítòótọ́; ìlú yìí ni wọn fi ọba ìlú Asiria lọ́wọ́.’

31 "ṣe tẹ́Hesekiah. Èyí ni ohun ọba Asiria , Fi ̀bùn ojúrere mi, o jáde tọ̀ .Nígbà náà olúkúlùkù yín yóò jẹun láti inú àjàrà rẹ̀ àti igi ̀pọ̀tọ́, yóò mu omi láti inú àmù rẹ̀, 32 títí èmi yóò fi lọ ilé gẹ́gẹ́ i tìrẹ, ilẹ̀ ọkà àti ọtí wáìnì, ilẹ̀ oúnjẹ àti ọgbà àjàrà, ilẹ̀ òróró olifi àti ti ilẹ̀ oyin; yàn ìyè ṣe yàn ikú!

"ṣe gbọ́ Hesekiah, nítorí ó ń tàn yín ó ba , Olúwa yóò gbà ?33 Ṣé òrìṣà àwọn orílẹ̀-èdè kankan ti gba ilé rẹ lọ́wọ́ àwọn ọba Asiria? 34 Níbo ni àwọn òrìṣà Hamati àti Arpadi gbé ? Níbo ni àwọn òrìṣà Sefarfaimi, Hena àti Iffa gbé ? Wọ́n ha gba Samaria kúrò lọ́wọ́ mi ? 35 Ta ni nínú gbogbo àwọn òrìṣà ilẹ̀ yìí ó ti gbìyànjú láti gba ilẹ̀ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ mi? Báwo ni Olúwa yóò ṣe gba Jerusalẹmu kúrò lọ́wọ́ mi?"

36 Ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ènìyàn náà dákẹ́ síbẹ̀ wọn sọ ohunkóhun, láti fi fèsì, nítorí ọba ti paláṣẹ, "ṣe a lóhùn."

37 Nígbà náà Eliakimu ọmọ Hilkiah olùtọ́ààfin, Ṣebna akọ̀àti Joah ọmọ Asafu akọ̀ránṣẹ́ lọ ̀dọ̀ Hesekiah, pẹ̀aṣọ wọn yíya, ó fún un ohun olùdarí pápá ti sọ.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também