Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 13

Jehoahasi ọba Israẹli

1 ọdún kẹtàlélógún ti Joaṣi ọmọ ọba Ahasiah ti Juda, Jehoahasi ọmọ Jehu di ọba Israẹli Samaria. Ó jẹ ọba fún ọdún mẹ́tàdínlógún. 2 Ó ṣe búburú níwájú Olúwa nípa títẹ̀̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, èyí ó ti fa Israẹli láti , yípadà kúrò nínú wọn. 3 Bẹ́̀ ni ìbínú Olúwa ru àwọn ọmọ Israẹli, àti fún ìgbà pípẹ́, ó fi wọ́n pamọ́ abẹ́ agbára ọba Hasaeli ọba Siria àti Beni-Hadadi ọmọ rẹ̀.

4 Nígbà náà Jehoahasi kígbe ó ojúrere Olúwa, Olúwa tẹ́i. Nítorí ó ọba Siria ti ń ni Israẹli lára gidigidi. 5 Olúwa pèsè olùgbàlà fún Israẹli, wọ́n kúrò lọ́wọ́ agbára Siria. Bẹ́̀ ni àwọn ọmọ Israẹli gbé nínú ilé ara wọn gẹ́gẹ́ wọ́n ti tẹ́lẹ̀. 6 Ṣùgbọ́n wọn yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ ilé Jeroboamu, èyí ó ti fa Israẹli láti , wọ́n tẹ̀síwájú nínú rẹ̀, ère òrìṣà Aṣerah síbẹ̀ Samaria pẹ̀.

7 ohùn kan wọ́n fi sílẹ̀ ti ọmọ-ogun Jehoahasi àyàfi àádọ́ta ọkùnrin ẹlẹ́ṣin, kẹ̀kẹ́ mẹ́wàá, àti ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) ọmọ-ogun ẹlẹ́ṣẹ̀, nítorí ọba Siria ti pa ìyókù run, ó ṣe wọ́n eruku nígbà pípa ọkà.

8 Fún ti ìyókù ìṣe Jehoahasi fún ìgbà, ó fi jẹ ọba, gbogbo ohun ó ṣe àti àṣeyọrí rẹ̀ ṣé a kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli? 9 Jehoahasi pẹ̀àwọn baba rẹ̀. A sin ín Samaria. Jehoaṣi ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Jehoaṣi ọba Israẹli

10 ọdún kẹtàdínlógójì Joaṣi ọba Juda, Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi di ọba Israẹli Samaria ó jẹ ọba fún ọdún mẹ́rìndínlógún. 11 Ó ṣe búburú ojú Olúwa, yípadà kúrò nínú ̀kankan nínú ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati èyí ó ti ti Israẹli láti . Ó tẹ̀síwájú nínú wọn.

12 Fún ti ìyókù iṣẹ́ Jehoaṣi fún ìgbà ó fi jẹ ọba, gbogbo ohun ó ṣe, pẹ̀àṣeyọrí rẹ̀ pẹ̀ogun rẹ̀ Amasiah ọba Juda, ṣé a kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli? 13 Jehoaṣi sinmi pẹ̀àwọn baba a rẹ̀. Jeroboamu rọ́rẹ̀ lórí ìtẹ́. A sin Jehoaṣi Samaria pẹ̀àwọn ọba Israẹli.

14 Nísinsin yìí, Eliṣa ń jìyà lọ́wọ́ àìsàn, lọ́wọ́ èyí ó . Jehoaṣi ọba Israẹli lọ láti lọ ó, ó sọkún lórí rẹ̀. "Baba mi! Baba mi!" Ó sọkún. "Àwọn kẹ̀kẹ́ àti àwọn ọkùnrin ẹlẹ́ṣin Israẹli!"

15 Eliṣa , "ọrun kan àti àwọn ọfà," ó ṣe bẹ́̀. 16 "ọrun ọwọ́ rẹ." Ó fún ọba Israẹli. Nígbà ó ti u, Eliṣa ọwọ́ rẹ̀ ọwọ́ ọba.

17 "Ṣí fèrèsé apá ìlà-oòrùn," ó , pẹ̀ó ṣí i: "Ta á!" Eliṣa , ó ta á. "Ọfà ìṣẹ́gun Olúwa; ọfà ìṣẹ́gun lórí Siria!" Eliṣa kéde. "Ìwọ yóò pa àwọn ará Siria run pátápátá Afeki."

18 Nígbà náà ó , "àwọn ọfà náà," ọba wọn. Eliṣa fún un , "Lu ilẹ̀." Ó ú lẹ́̀mẹ́ta, ó dáwọ́ dúró. 19 Ènìyàn Ọlọ́run bínú i, ó , "Ìwọ ti lu ilẹ̀ ̀̀márùn ún tàbí ̀̀mẹ́, nígbà náà, ìwọ ti ṣẹ́gun Siria àti pa á run pátápátá ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìwọ yóò ṣẹ́gun rẹ̀ ̀̀mẹ́ta péré."

20 Eliṣa a sin ín.

Ẹgbẹ́ àwọn ará Moabu máa ń wọ orílẹ̀-èdè gbogbo àmọ́dún. 21 àwọn ọmọ Israẹli kan ti ń sin òkú ọkùnrin kan, lójijì wọ́n ẹgbẹ́ àwọn oníjadì, bẹ́̀ ni wọ́n ju òkú ọkùnrin náà sínú ibojì Eliṣa. Nígbà ara ọkùnrin náà kan egungun Eliṣa, ó padà ayé, ó dúró ẹsẹ̀ rẹ̀.

22 Hasaeli ọba Siria ni Israẹli lára gbogbo àkókò Jehoahasi fi jẹ ọba. 23 Ṣùgbọ́n Olúwa ṣàánú fún wọn ó ìyọ́, ó fiyèsí wọn nítorí májẹ̀rẹ̀ pẹ̀Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu. Títí di ọjọ́ òní, í ṣe ìfẹ́ inú rẹ̀ láti pa wọ́n run tàbí wọn lọ níwájú rẹ̀.

24 Hasaeli ọba Siria , Beni-Hadadi ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba. 25 Nígbà náà, Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi gbà padà kúrò lọ́wọ́ Beni-Hadadi ọmọ Hasaeli àwọn ìlú ó ti gbà nínú ogun látọ̀dọ̀ baba rẹ̀ Jehoahasi. ̀̀mẹta, Jehoaṣi ṣẹ́gun rẹ̀, bẹ́̀ ni ó gba ìlú àwọn ọmọ Israẹli padà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também