Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 25

1 Nígbà ó di ọdún kẹsànán ìjọba Sedekiah. ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹwàá, Nebukadnessari ọba Babeli yan lọ Jerusalẹmu pẹ̀gbogbo àwọn ogun rẹ̀. Ó pàgọ́ ìta ìlú ó mu àwọn iṣẹ́ ìdọ̀fi gbogbo rẹ̀ . 2 Ìlú náà ìhámọ́ lábẹ́ ìgbóguntì títí di ọdún kọkànlá ti ọba Sedekiah.

3 Nígbà ó di ọjọ́ kẹsànán oṣù kẹrin, ìyàn ìlú ó jẹ́ oúnjẹ fún àwọn ènìyàn láti jẹ. 4 Nígbà náà odi ìlú náà fọ́nká, gbogbo àwọn ọmọ-ogun sálọ òru láti ẹnu-ọ̀bodè láàrín ògiri méjì ẹgbẹ́ ọgbà ọba, àwọn ará Babeli wọ́n ìlú náà . Wọ́n sálọ ìkọjá Arabah. 5 Ṣùgbọ́n ogun àwọn ará Kaldea lépa ọba, wọ́n e pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jeriko. Gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ kúrò ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n túká, 6 wọ́n un.

Wọ́n lọ ̀dọ̀ ọba Babeli Ribla, níbi à ti ṣe ìdájọ́ lórí rẹ̀. 7 Wọ́n pa ọmọ Sedekiah níwájú rẹ̀, wọ́n yọ ojú rẹ̀ jáde, wọn é pẹ̀̀wọ̀n idẹ wọ́n gbe é lọ Babeli.

8 ọjọ́ keje oṣù karùn-ún, ọdún kọkàndínlógún ti Nebukadnessari ọba Babeli, Nebusaradani olórí ̀ṣọ́, ìránṣẹ́ ọba Babeli Jerusalẹmu; 9 ó finá ilé Olúwa, ilé ọba àti gbogbo àwọn ó Jerusalẹmu àti gbogbo ilé ńlá ńlá ni ó dáná sun. 10 Gbogbo àwọn ogun Babeli, ó lọ́dọ̀ olórí ̀ṣọ́, ògiri ó Jerusalẹmu lulẹ̀. 11 Nebusaradani olórí ̀ṣọ́ gbogbo àwọn tálákà àti gbogbo àwọn ó ìlú, ìgbèkùn lọ Babeli, pẹ̀àwọn ó ya lọ, ó ya tọ ọba Babeli lọ, àti ìyókù àwọn ènìyàn náà. 12 Ṣùgbọ́n olórí ̀ṣọ́ fi àwọn tálákà ènìyàn ilẹ̀ náà sílẹ̀ láti máa bojútó àjàrà àti láti máa ṣe aroko.

13 Àwọn ará Babeli fọ́ ̀wọ̀n idẹ wọ̀n-ọn-nì àti àwọn ìjókòó wọ̀n-ọn-nì, àti agbada idẹ títóbi wọ̀n-ọn-nì ń bẹ ilé Olúwa, àwọn ará Babeli fọ́ túútúú, wọ́n idẹ náà lọ Babeli. 14 Wọ́n àwọn ìkòkò wọ̀n-ọn-nì, ọkọ́ wọ̀n-ọn-nì, ̀fìtílà wọ̀n-ọn-nì, síbí wọ̀n-ọn-nì àti gbogbo ohun èlò idẹ wọ̀n-ọn-nì wọ́n fi ṣiṣẹ́ lọ. 15 Olórí ̀ṣọ́ ohun ìfọnná wọ̀n-ọn-nì, àti ọpọ́n wọ̀n-ọn-nì, èyí wọ́n fi wúrà àti fàdákà ṣe lọ.

16 Àwọn ̀wọ́n méjì, agbada ńlá kan, àti ìjókòó wọ̀n-ọn-nì Solomoni ti ṣe fún ilé Olúwa, idẹ ni gbogbo ohun èló wọ̀nyí, ó ju èyí a wọ́n lọ. 17 Gíga ̀wọ́n kọ̀̀kan jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ méjìdínlógún, àti ọnà-orí rẹ̀ idẹ ni: àti gíga ọnà-orí náà ni ìgbọ̀nwọ́ mẹ́ta; àti iṣẹ́ híhun náà, àti àwọn pomegiranate ó lórí ọnà-orí náà yíká, gbogbo rẹ̀ ti idẹ ni: gẹ́gẹ́ ̀wọ́n yìí ni ̀wọ́n kejì pẹ̀iṣẹ́ híhun.

18 Olórí àwọn ̀ṣọ́ gẹ́gẹ́ ẹlẹ́wọ̀n, Seraiah olórí àwọn àlùfáà, Sefaniah àlùfáà kejì, àti àwọn olùṣọ́ ìloro mẹ́ta. 19 Àti àwọn ó ìlú, ó ìwẹ̀kan ó fi se olórí àwọn ológun, àti ọkùnrin márùn-ún nínú àwọn ń gba ọba ìmọ̀ràn. Ó tún akọ̀olórí ogun, ó ń to àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà àti ọgọ́ta nínú àwọn ènìyàn rẹ̀ wọ́n ìlú. 20 Nebusaradani, olórí àwọn ̀ṣọ́ gbogbo wọn, ó wọn tọ ọba Babeli Ribla. 21 Níbẹ̀ Ribla, ilẹ̀ Hamati, ọba Babeli kọlù wọ́n.

Bẹ́̀ ni a Juda kúrò ilẹ̀ rẹ̀.

22 Nebukadnessari ọba Babeli ó Gedaliah ọmọ Ahikamu ọmọ Ṣafani, láti jẹ baálẹ̀ lórí àwọn ènìyàn ó sílẹ̀ ilẹ̀ Juda. 23 Nígbà gbogbo àwọn olórí ogun àti àwọn ọkùnrin wọn gbọ́ ọba Babeli ti yan Gedaliah gẹ́gẹ́ baálẹ̀, wọ́n ̀dọ̀ Gedaliah ni Mispa. Iṣmaeli ọmọ Netaniah, Johanani ọmọ Karea, Seraiah ọmọ Tanhumeti ará Netofa, Jaaṣaniah ọmọ ará Maakati, àti àwọn ọkùnrin wọn. 24 Gedaliah búra láti fi àwọn ènìyàn rẹ̀ lójú. "ṣe bẹ̀àwọn ìjòyè ará Babeli," ó , "máa gbé ilẹ̀ náà sin ọba Babeli, yóò dára fún un yín."

25 oṣù keje, ni Iṣmaeli ọmọ Netaniah, ọmọ Eliṣama, nínú irú-ọmọ ọba, pẹ̀àwọn ọkùnrin mẹ́wàá, ó kọlù Gedaliah àti pẹ̀àwọn ọkùnrin mẹ́wàá ará Juda àti àwọn ará Babeli ó pẹ̀rẹ̀ Mispa. 26 Nítorí èyí, gbogbo àwọn ènìyàn láti ẹni kékeré títí ẹni ńlá, àti pẹ̀àwọn olórí ogun, sálọ si Ejibiti nítorí ̀àwọn ará Babeli.

Wọ́n Jehoiakini sílẹ̀

27 25.27-30: Jr 52.31-34. ọdún kẹtàdínlógójì ìgbèkùn Jehoiakini ọba Juda, oṣù kejìlá, ọjọ́ kẹtàdínlógbọ̀n oṣù, Efili-Merodaki ọba Babeli, ọdún ó bẹ̀rẹ̀ jọba, ó gbé orí Jehoiakini ọba Juda sókè, ó sílẹ̀ kúrò nínú túbú. 28 Ó ń sọ̀rọ̀ rere fún un, ó gbé ìtẹ́ rẹ̀ ga ju ìtẹ́ àwọn ọba tókù lọ ó pẹ̀rẹ̀ Babeli. 29 Ó pàrọ̀ àwọn aṣọ túbú rẹ̀, ó ń jẹun gbogbo ìgbà iwájú rẹ̀ gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀. 30 ojoojúmọ́, ọba fún Jehoiakini ìpín tirẹ̀ ó ń bẹ láààyè.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também