Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 1

Ìran Adamu títí de Abrahamu

Títí ọmọkùnrin Noa

1 1.1-53: Gẹ 5; 10; 11; 25; 36. Adamu, Seti, Enoṣi,

2 Kenani, Mahalaleli, Jaredi,

3 Enoku, Metusela, Lameki,

Noa.

4 Àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti.

Àwọn Ọmọ Jafeti

5 Àwọn ọmọ Jafeti ni:

Gomeri, Magogu, Madai; Jafani, Tubali, Meṣeki àti Tirasi.

6 Àwọn ọmọ Gomeri ni:

Aṣkenasi, Rifati àti Togarma.

7 Àwọn ọmọ Jafani ni:

Eliṣa, Tarṣiṣi, Kittimu, àti Dodanimu.

Àwọn ọmọ Hamu

8 Àwọn ọmọ Hamu ni:

Kuṣi, Ejibiti, Puti, àti Kenaani.

9 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:

Seba, Hafila, Sabta, Raama, àti Sabteka.

Àwọn ọmọ Raama:

Ṣeba àti Dedani.

10 Kuṣi Nimrodu

ẹni ó di alágbára jagunjagun ayé.

11 Ejibiti

Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Naftuhimu, 12 Patrusimu, Kasluhimu (láti ̀dọ̀ ẹni àwọn ará Filistini ti ) àti àwọn ará Kaftorimu.

13 Kenaani Sidoni àkọ́rẹ̀,

àti Heti, 14 àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi, 15 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini, 16 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.

Àwọn ará Ṣemu.

17 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:

Elamu, Aṣuri, Arfakṣadi, Ludi àti Aramu.

Àwọn ọmọ Aramu:

Usi, Huli, Geteri, àti Meṣeki.

18 Arfakṣadi Ṣela,

Ṣela Eberi.

19 Eberi ọmọ méjì:

̀kan ń jẹ́ Pelegi, nítorí ìgbà ọjọ́ rẹ̀ ni ilẹ̀ ya; orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Joktani.

20 Joktani

Almodadi, Ṣelefi, Hasarmafeti, Jera. 21 Hadoramu, Usali, Dikla, 22 Ebali, Abimaeli, Ṣeba. 23 Ofiri, Hafila, àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.

24 Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,

25 Eberi, Pelegi. Reu,

26 Serugu, Nahori, Tẹra,

27 àti Abramu (ń ṣe Abrahamu).

Ìdílé Abrahamu

28 Àwọn ọmọ Abrahamu: Isaaki àti Iṣmaeli.

Àwọn ọmọ Hagari

29 Èyí ni àwọn ọmọ náà:

Nebaioti àkọ́Iṣmaeli: Kedari, Adbeeli, Mibsamu, 30 Miṣima, Duma, Massa, Hadadi, Tema, 31 Jeturi, Nafiṣi, àti Kedema.

Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Iṣmaeli.

Àwọn ọmọ Ketura

32 Àwọn ọmọ Ketura, obìnrin Abrahamu:

Simrani, Jokṣani Medani, Midiani Iṣbaki àti Ṣua.

Àwọn ọmọ Jokṣani:

Ṣeba àti Dedani.

33 Àwọn ọmọ Midiani:

Efani, Eferi, Hanoku, Abida àti Eldaa.

Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Ketura.

Àwọn Ìran Sara

34 Abrahamu jẹ́ baba Isaaki.

Àwọn ọmọ Isaaki:

Esau àti Israẹli.

Àwọn ọmọ Esau

35 Àwọn ọmọ Esau:

Elifasi, Reueli, Jeuṣi, Jalamu, àti Kora.

36 Àwọn ọmọ Elifasi:

Temani, Omari, Sefi, Gatamu àti Kenasi;

láti Timna: Amaleki.

37 Àwọn ọmọ Reueli:

Nahati, Sera, Ṣamma àti Missa.

Àwọn ènìyàn Seiri Edomu

38 Àwọn ọmọ Seiri:

Lotani, Ṣobali, Sibeoni, Ana, Diṣoni, Eseri àti Diṣani.

39 Àwọn ọmọ Lotani:

Hori àti Homamu: Timna ni arábìnrin Lotani.

40 Àwọn ọmọ Ṣobali:

Afiani, Manahati, Ebali, Ṣefo àti Onamu.

Àwọn ọmọ Sibeoni:

Aiah àti Ana.

41 Àwọn ọmọ Ana:

Diṣoni.

Àwọn ọmọ Diṣoni:

Hemdani, Eṣbani, Itrani, àti Kerani.

42 Àwọn ọmọ Eseri:

Bilhani, Saafani àti Akani.

Àwọn ọmọ Diṣani:

Usi àti Arani.

Àwọn alákòóso Edomu

43 Àwọn wọ̀nyí ni ọba ó jẹ Edomu, ó di ọba kankan jẹ lórí Israẹli:

Bela ọmọ Beori, orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.

44 Nígbà Bela , Jobabu ọmọ Sera ti Bosra jẹ ọba ipò rẹ̀.

45 Nígbà Jobabu , Huṣamu láti ilẹ̀ Temani jẹ ọba ipò rẹ̀.

46 Nígbà Huṣamu , Hadadi ọmọ Bedadi ó kọlu Midiani ìgbẹ́ Moabu, ó jẹ ọba ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.

47 Nígbà Hadadi , Samla láti Masreka, ó jẹ ọba ipò rẹ̀.

48 Samla , Saulu ti Rehoboti létí odò jẹ ọba ipò rẹ̀.

49 Nígbà Saulu , Baali-Hanani, ọmọ Akbori jẹ ọba ipò rẹ̀.

50 Nígbà Baali-Hanani , Hadadi ni ó jẹ ọba ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu. 51 Hadadi pẹ̀.

Àwọn baálẹ̀ Edomu ni:

baálẹ̀ Timna, baálẹ̀ Alfa, baálẹ̀ Jeteti 52 baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni. 53 Baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari, 54 Magdieli àti Iramu.

Àwọn wọ̀nyí ni baálẹ̀ Edomu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também