Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 5

Rubeni

1 5.1-26: Gẹ 46.9; Nu 26.5,6. Ǹjẹ́ àwọn ọmọ Reubeni, àkọ́Israẹli. (Nítorí òun ni àkọ́; ṣùgbọ́n, ó ti ṣe ó ba ibùsùn baba rẹ̀ jẹ́, a fi ogún ìbí rẹ̀ fún àwọn ọmọ Josẹfu ọmọ Israẹli: a yóò ka ìtàn ìdílé náà gẹ́gẹ́ ipò ìbí. 2 Nítorí Juda borí àwọn arákùnrin rẹ̀, àti lọ́dọ̀ rẹ̀ ni aláṣẹ ti ń jáde ; ṣùgbọ́n ogún ìbí jẹ́ ti Josẹfu), 3 àwọn ọmọ Reubeni àkọ́Israẹli ni:

Hanoku àti Pallu, Hesroni àti Karmi.

4 Àwọn ọmọ Joẹli:

Ṣemaiah ọmọ rẹ̀, Gogu ọmọ rẹ̀,

Ṣimei ọmọ rẹ̀. 5 Mika ọmọ rẹ̀,

Reaiah ọmọ rẹ̀, Baali ọmọ rẹ̀.

6 Beera ọmọ rẹ̀, Tiglat-Pileseri ọba Asiria ìgbèkùn lọ. Ìjòyè àwọn ọmọ Reubeni ni Beera jẹ́.

7 Àti àwọn arákùnrin rẹ̀ nípa ìdílé wọn, nígbà a ń ka ìtàn ìdílé ìran wọn:

Jeieli àti Sekariah ni olórí, 8 àti Bela ọmọ Asasi ọmọ Ṣema, ọmọ Joẹli.

Wọ́n ń gbé Aroeri àní títí Nebo àti Baali-Meoni. 9 Àti níhà àríwá, o tẹ̀lọ títí àtiwọ aginjù láti odò Eufurate; nítorí ẹran ̀sìn wọn pọ̀ i ilẹ̀ Gileadi.

10 Àti ọjọ́ Saulu, wọ́n àwọn ọmọ Hagari jagun, ẹni ó ṣubú nípa ọwọ́ wọn; wọ́n ń gbé inú àgọ́ wọn gbogbo ilẹ̀ àríwá Gileadi.

Ìdílé Gadi

11 Àti àwọn ọmọ Gadi ń gbé lékè wọn, ilẹ̀ Baṣani títí Saleka:

12 Joẹli jẹ́ olórí, Ṣafamu ìran ọmọ Janai, àti Ṣafati ni Baṣani.

13 Àti àwọn arákùnrin wọn ti ilẹ̀ àwọn baba wọn :

Mikaeli, Meṣullamu Ṣeba, Jorai, Jaka, Sia àti Eberi méje.

14 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Abihaili, ọmọ Huri, ọmọ Jeroa, ọmọ Gileadi, ọmọ Mikaeli, ọmọ Jeṣiṣai, ọmọ Jado, ọmọ Busi.

15 Ahi, ọmọ Adbeeli, ọmọ Guni, olórí ilé àwọn baba wọn.

16 Wọ́n ń gbé Gileadi Baṣani àti nínú àwọn ìlú rẹ̀, àti nínú gbogbo ìgbèríko Ṣaroni, agbègbè wọn.

17 Gbogbo wọ̀nyí ni a nípa ìtàn ìdílé, ọjọ́ Jotamu ọba Juda, àti ọjọ́ Jeroboamu ọba Israẹli.

18 Àwọn ọmọ Reubeni, àti àwọn ọmọ Gadi, àti ààbọ̀ ̀Manase, nínú àwọn ọkùnrin alágbára wọ́n ń gbé asà àti idà, wọ́n ń fi ọrun tafà, wọ́n mòye ogun, jẹ́ ̀kẹ́ méjì ó ẹgbẹ̀rìnlélógún dín ogójì (47,760) ènìyàn, ó jáde lọ ogún náà. 19 Wọ́n àwọn ọmọ Hagari jagun, pẹ̀Jeturi, àti Nafiṣi àti Nadabu. 20 Nígbà wọ́n ìrànlọ́wọ́ gbà si, a fi àwọn ọmọ Hagari wọn lọ́wọ́, àti gbogbo àwọn ó pẹ̀wọn; nítorí tiwọn pe Ọlọ́run ogun náà, òun gbọ́ ̀bẹ̀ wọn; nítorí wọ́n gbẹ́kẹ̀ wọn e. 21 Wọ́n ẹran ̀sìn wọn lọ; ìbákasẹ ẹgbàá mẹ́̀́dọ́gbọ̀n (50,000) àti àgùntàn ̀kẹ́ méjìlá ó ẹgbàárùn-ún (250,000), àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì (2,000), àti ènìyàn ̀kẹ́ márùn-ún (100,000). 22 Nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó ṣubú a pa, nítorí láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ni ogun náà, wọ́n jókòó ipò wọn títí di ìgbà ìkólọ ìgbèkùn.

Ààbọ̀ ̀Manase

23 Àwọn ọmọkùnrin ààbọ̀ ̀Manase ń gbé ilẹ̀ náà: wọ́n i láti Baṣani títí Baali-Hermoni, àti Seniri àti títí òkè Hermoni.

24 Wọ̀nyí ni àwọn olórí ilé àwọn baba wọn. Eferi, Iṣi, Elieli, Asrieli, Jeremiah, Hodafiah àti Jahdieli àwọn alágbára akọni ọkùnrin, ọkùnrin olókìkí, àti olórí ilé àwọn baba wọn. 25 Wọ́n ṣẹ̀ Ọlọ́run àwọn baba wọn, wọ́n ṣe àgbèrè tọ àwọn ọlọ́run ènìyàn ilẹ̀ náà lẹ́yìn, Ọlọ́run ti parun iwájú wọn. 26 Nítorí náà Ọlọ́run Israẹli ru ̀Pulu ọba Asiria sókè (èyí ni Tiglat-Pileseri ọba Asiria), ó si wọn lọ, àní àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, àti ààbọ̀ ̀Manase lọ ìgbèkùn. Ó wọn Hala, àti Habori, àti Harani, àti etí odò Gosani; títí òní yìí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também