Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 23

Àwọn ará Lefi

1 Nígbà Dafidi dàgbà, ó di arúgbó, ó fi Solomoni ọmọ rẹ̀ jẹ ọba lórí Israẹli.

2 Ó gbogbo àgbàgbà Israẹli jọ, àti gẹ́gẹ́ àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi. 3 Àwọn ọmọ Lefi láti ọgbọ̀n ọdún tàbí bẹ́̀ lọ ni wọ́n àpapọ̀ iye àwọn ọkùnrin wọn jẹ́ ẹgbàá mọ́kàndínlógún (38,000). 4 Dafidi pe, ti èyí, ẹgbàá méjìlá (24,000) ni wọn jẹ́ alábojútó iṣẹ́ ilé fún Olúwa àti ẹgbẹ̀rún mẹ́(6,000) ni ó ṣe olórí àti onídàájọ́. 5 Ẹgbàajì (4,000) ni ó jẹ́ olùtọ́ẹnu-ọ̀àti ẹgbàajì (4,000) ni o jẹ́ ẹni ti yóò máa yin Olúwa pẹ̀ohun èlò orin, mo ti ṣe èyí fún ìdí pàtàkì yìí.

6 Dafidi pín àwọn ọmọ Lefi ẹgbẹgbẹ́ láàrín àwọn ọmọ Lefi: Gerṣoni, Kohati àti Merari.

Àwọn ọmọ Gerṣoni

7 Àwọn ó jẹ́ ọmọ Gerṣoni:

Laadani àti Ṣimei.

8 Àwọn ọmọ Laadani

Jehieli ẹni àkọ́kọ́, Setamu àti Joẹli, mẹ́ta gbogbo wọn.

9 Àwọn ọmọ Ṣimei:

Ṣelomiti, Hasieli àti Harani mẹ́ta gbogbo wọn.

Àwọn wọ̀nyí ni olórí àwọn ìdílé Laadani.

10 Àti ọmọ Ṣimei:

Jahati, Sina, Jeuṣi àti Beriah.

Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Ṣimei mẹ́rin ni gbogbo wọn.

11 Jahati ni alákọ́kọ́ Sinah ni ẹlẹ́̀kejì, ṣùgbọ́n Jeuṣi àti Beriah àwọn ọmọ púpọ̀; bẹ́̀ ni wọ́n ka ara wọn ìdílé kan pẹ̀ìfilé lọ́wọ́ kan.

Àwọn ará Kohati

12 Àwọn ọmọ Kohati:

Amramu, Isari, Hebroni àti Usieli mẹ́rin ni gbogbo wọn.

13 23.13: El 28.1. Àwọn ọmọ Amramu.

Aaroni àti Mose.

A ya Aaroni sọ́tọ̀ òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ títí láéláé, láti kọjú ohun mímọ́ jùlọ, láti fi ẹbọ sísun níwájú Olúwa, láti máa ṣe òjíṣẹ́ níwájú rẹ̀ àti láti kéde ìbùkún orúkọ rẹ̀ títí láéláé. 14 Àwọn ọmọ Mose ènìyàn Ọlọ́run ni wọ́n gẹ́gẹ́ apá kan ̀Lefi.

15 Àwọn ọmọ Mose:

Gerṣomu àti Elieseri.

16 Àwọn ọmọ Gerṣomu:

Ṣubaeli ni alákọ́kọ́.

17 Àwọn ọmọ Elieseri:

Rehabiah ni ẹni àkọ́kọ́.

Elieseri tún ọmọ mìíràn, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Rehabiah wọ́n pọ̀ níye.

18 Àwọn ọmọ Isari:

Ṣelomiti ni ẹni àkọ́kọ́.

19 Àwọn ọmọ Hebroni:

Jeriah ni ẹni àkọ́kọ́, Amariah ni ẹni ̀̀kejì,

Jahasieli ni ̀̀kẹ́ta àti Jekameamu ̀̀kẹrin.

20 Àwọn ọmọ Usieli:

Mika ni àkọ́kọ́ àti Iṣiah ̀̀kejì.

Àwọn ará Merari

21 Àwọn ọmọ Merari:

Mahili àti Muṣi.

Àwọn ọmọ Mahili:

Eleasari àti Kiṣi.

22 Eleasari pẹ̀àìní àwọn ọmọkùnrin: Ó ọmọbìnrin nìkan. Àwọn ọmọ ̀gbọ́n, àwọn ọmọ Kiṣi, fẹ́ wọn.

23 Àwọn ọmọ Muṣi:

Mahili, Ederi àti Jerimoti mẹ́ta ni gbogbo wọn.

24 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Lefi ìdílé wọn. Olórí ìdílé gẹ́gẹ́ wọ́n ti fi orúkọ sílẹ̀ lábẹ́ orúkọ wọn, ó wọn ẹyọ kọ̀̀kan, , àwọn òṣìṣẹ́ ó jẹ́ ogún ọdún tàbí bẹ́̀ lọ ń ṣiṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa. 25 Nítorí Dafidi ti sọ , "Níwọ̀n ìgbà Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ti fi ìsinmi fún àwọn ènìyàn ó ń gbé Jerusalẹmu títí láéláé, 26 àwọn ọmọ Lefi tún ru àgọ́ tàbí ̀kankan lára àwọn ohun èlò wọ́n ń níbi ìsìn rẹ̀." 27 Gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi , àwọn ọmọ Lefi, wọ́n wọ́n, bẹ̀rẹ̀ láti orí àwọn ọmọ ogún ọdún tàbí bẹ́̀ lọ.

28 Iṣẹ́ àwọn ọmọ Lefi ni láti ran àwọn ọmọ Aaroni lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ wọn fún ti ilé Olúwa: láti lábẹ́ ìkáwọ́ agbára ìlú, àti ̀gbẹ́ ilé, àti ìwẹ̀nùmọ́ ti gbogbo ohun ìyàsọ́tọ̀ àti ṣíṣe ohun í ṣe iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa. 29 Wọ́n ìkáwọ́ àkàrà wọ́n jáde láti orí tábìlì, àti ìyẹ̀fun fún ẹbọ, àti àkàrà aláìwú, àti fún púpọ̀ àti èyí a pòpọ̀, àti gbogbo onírúurú ìwọ̀n àti wíwọ̀n àti òsùwọ̀n. 30 Wọ́n gbọdọ̀ dúró gbogbo òwúrọ̀ láti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa. Wọ́n gbọdọ̀ ṣe irú kan náà àṣálẹ́. 31 Àti láti ẹbọ sísun fún Olúwa ọjọ́ ìsinmi àti àsìkò oṣù tuntun àti àjọ̀dún a yàn. Wọ́n gbọdọ̀ sìn níwájú Olúwa lójoojúmọ́ iye yẹ àti ̀a ti pàṣẹ fún wọn.

32 Bẹ́̀ ni nígbà náà, àwọn ọmọ Lefi gbé ìgbékalẹ̀ jáde fún ìpàdé àgọ́, fún Ibi Mímọ́ àti, lábẹ́ àwọn arákùnrin àwọn ọmọ Aaroni fún ìsìn ilé Olúwa.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também