Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 25

Àwọn akọrin

1 Pẹ̀lúpẹ̀Dafidi àti àwọn olórí àwọn ọmọ-ogun, ó díẹ̀ sọ́tọ̀ lára àwọn ọmọ Asafu, Hemani àti Jedutuni fún ìsìn àsọtẹ́lẹ̀, pẹ̀dùùrù, ohun èlò orin olókùn àti kimbali. Èyí àwọn iye àwọn ọkùnrin ẹni ó ṣe oníṣẹ́ ìsìn yìí.

2 Nínú àwọn ọmọ Asafu:

Sakkuri, Josẹfu, Netaniah àti Asarela, àwọn ọmọ Asafu ni wọ́n lábẹ́ ìbojútó Asafu, ẹni ó sọtẹ́lẹ̀ lábẹ́ ìbojútó ọba.

3 Gẹ́gẹ́ ti Jedutuni, nínú àwọn ọmọkùnrin rẹ̀:

Gedaliah, Seri, Jeṣaiah, Ṣimei, Haṣabiah àti Mattitiah, mẹ́nínú gbogbo wọn, lábẹ́ ìbojútó baba wọn Jedutuni, ẹni ó sọtẹ́lẹ̀, ẹni ó lo dùùrù láti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa.

4 Gẹ́gẹ́ ti Hemani, nínú àwọn ọmọ rẹ̀:

Bukkiah, Mattaniah, Usieli, Ṣubaeli àti Jerimoti; Hananiah, Hanani, Eliata, Giddalti, àti Romamtieseri, Joṣbekaṣa, Malloti, Hotiri, Mahasiotu. 5 Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Hemani àti wòlíì ọba. Wọ́n fi wọ́n fún nípa ìlérí Ọlọ́run láti máa gbé ìwo sókè. Ọlọ́run fún Hemani ọmọkùnrin mẹ́rìnlá àti àwọn ọmọbìnrin mẹ́ta.

6 Gbogbo àwọn ọkùnrin yìí ni wọ́n lábẹ́ ìbojútó àwọn baba wọn fún ohun èlò orin ilé Olúwa, pẹ̀kimbali, ohun èlò orin olókùn àti dùùrù, fún ìsìn ilé Olúwa.

Asafu, Jedutuni àti Hemani lábẹ́ ọba. 7 Àwọn ìdílé wọn pẹ̀gbogbo àwọn ó mòye àti àwọn a kọ́ ohun èlò orin fún Olúwa, iye wọn jẹ́ ̀rìnlélúgba ó mẹ́jọ (288). 8 Kékeré àti àgbà bákan náà, olùkọ́ àti gẹ́gẹ́ ti akẹ́kọ̀́, ṣẹ́ kèké fún iṣẹ́ wọn.

9 Kèké èkínní èyí ó jẹ́ ti Asafu, jáde Josẹfu, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

èkejì ni Gedaliah, òun àti àwọn ìdílé rẹ̀ àti àwọn ọmọ rẹ̀, méjìlá

10 ẹlẹ́̀kẹta Sakkuri, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé, méjìlá

11 ẹlẹ́̀kẹrin Isiri, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

12 ẹlẹ́̀karùnún Netaniah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

13 ẹlẹ́̀kẹfà Bukkiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

14 ẹlẹ́̀keje Jasarela, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

15 ẹlẹ́̀kẹjọ Jeṣaiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

16 ẹlẹ́̀kẹsàn-án Mattaniah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

17 ẹlẹ́̀kẹwàá Ṣimei, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

18 ẹlẹ́̀kọkànlá Asareeli, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

19 ẹlẹ́̀kẹjìlá Haṣabiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

20 ẹlẹ́̀kẹtàlá Ṣubaeli, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

21 ẹlẹ́̀kẹrìnlá Mattitiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

22 ẹlẹ́̀kẹẹ̀dógún Jerimoti, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

23 ẹlẹ́̀kẹrìndínlógún Hananiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

24 ẹlẹ́̀kẹtàdínlógún Joṣbekaṣa, àwọn ọmọ rẹ̀ jẹ́, méjìlá

25 ẹlẹ́̀kejìdínlógún Hanani, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

26 ẹlẹ́̀kọkàndínlógún Malloti, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

27 ogún Eliata, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

28 ẹlẹ́̀kọkànlélógún Hotiri, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

29 ẹlẹ́̀kejìlélógún Giddalti, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

30 ẹlẹ́̀kẹtàlélógún Mahasiotu, àwọn ọmọ rẹ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá

31 ẹlẹ́̀kẹrìnlélógún Romamtieseri àwọn ọmọ rẹ̀, àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também