Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 11

Dafidi di ọba lórí Israẹli

1 11.1-3: 2Sa 5.1-3. Gbogbo àwọn Israẹli ara wọn jọ pọ̀ ̀dọ̀ Dafidi Hebroni, wọ́n , "Ẹran-ara rẹ àti ̀jẹ̀ rẹ ni àwa í ṣe. 2 àtijọ́, kódà nígbà Saulu jẹ ọba, ìwọ ni ẹni ó darí Israẹli ojú ogun wọn. Olúwa Ọlọ́run rẹ fún , Ìwọ yóò jẹ́ olùṣọ́ Israẹli ènìyàn mi, ìwọ yóò jẹ́ olórí fún wọn.’ "

3 Nígbà gbogbo àwọn ìjòyè Israẹli wọ́n ti sọ́dọ̀ ọba Dafidi ni Hebroni. Ó ṣe májẹ̀pẹ̀wọn Hebroni níwájú Olúwa, wọ́n fi òróró yan Dafidi ọba lórí Israẹli, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa láti ọwọ́ Samuẹli.

Dafidi borí Jerusalẹmu

4 11.4-9: 2Sa 5.6-10. Dafidi àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jáde lọ Jerusalẹmu (ṣe Jebusi). Àwọn Jebusi ara ilẹ̀ náà ń gbé níbẹ̀. 5 Àwọn ará ìlú Jebusi fún Dafidi , "Ìwọ gbọdọ̀ wọ ìhín yìí ." Ṣùgbọ́n Dafidi ìlú odi Sionièyí í ṣe ìlú Dafidi.

6 Dafidi ti , "Ẹnikẹ́ni ó tètè kọlu àwọn ará Jebusi ni yóò di olórí àti balógun." Joabu ọmọ Seruiah kọ́kọ́ gòkè lọ, bẹ́̀ ni ó gba olórí.

7 Dafidi ń gbé inú ìlú odi, nítorí náà ni wọ́n fi ń é ni ìlú Dafidi. 8 Ó kọ́ àwọn ìlú náà yíkákiri; láti Millo yíkákiri; Joabu tún ìyókù àwọn ìlú náà ṣe. 9 Bẹ́̀ ni Dafidi ń ga, ó pọ̀ i, nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun pẹ̀rẹ̀.

Dafidi alágbára ọkùnrin

10 11.10-41: 2Sa 23.8-39. Àwọn wọ̀nyí ni ìjòyè alágbára ọkùnrin Dafidi, àwọn pẹ̀gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n fún ìjọba rẹ̀ àtìlẹ́yìn lágbára láti un tàn káàkiri gbogbo ilẹ̀, gẹ́gẹ́ Olúwa ti ṣèlérí. 11 Èyí ni iye àwọn akọni ọkùnrin Dafidi:

Jaṣobeamu ọmọ Hakumoni, òun ni olórí nínú àwọn ìjòyè, ó gbé ̀kọ̀ rẹ̀ sókè lórí àwọn ̀́dúnrún (300) ènìyàn, àwọn ẹni ó pa ogun ̀̀kan.

12 Lẹ́yìn rẹ̀ ni Eleasari ọmọ Dodo àwọn ará Ahohi, ̀kan lára àwọn mẹ́ta ọkùnrin alágbára. 13 Ó pẹ̀Dafidi Pasi-Dammimu nígbà àwọn ará Filistini ara wọn jọ láti jagun, níbi ilẹ̀ kan ó kún fún ọkà barle. Àwọn ènìyàn sálọ kúrò níwájú Filistini. 14 Ṣùgbọ́n wọ́n ìdúró wọn àárín pápá náà. Wọ́n gbà a wọ́n gún àwọn ará Filistini mọ́lẹ̀, Olúwa ìgbàlà ńlá fún wọn.

15 Mẹ́ta nínú àwọn ọgbọ̀n ìjòyè sọ̀kalẹ̀ tọ́ Dafidi lọ orí àpáta nínú ihò Adullamu, nígbà àwọn ẹgbẹ́ Filistini dúró àfonífojì orí òkè Refaimu. 16 àsìkò náà Dafidi ń bẹ nínú ìlú odi, ẹgbẹ́ ogun àwọn ará Filistini ń bẹ Bẹtilẹhẹmu. 17 Dafidi pòǹgbẹ fún omi ó , "Háà, ẹnìkan yóò ha bu omi láti inú kànga ̀gbẹ́ ẹnu-bodè Bẹtilẹhẹmu fún un mu?" 18 Bẹ́̀ ni àwọn mẹ́ta náà láti ogun ará Filistini, ó fa omi jáde láti inú kànga ̀gbẹ́ ẹnu-bodè Bẹtilẹhẹmu ó gbé padà tọ Dafidi . Ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti mu ú: dípò, ó jáde níwájú Olúwa. 19 "Ọlọ́run jẹ́ èmi ó ṣe ṣe èyí!" ó . "Ṣé èmi ó ̀jẹ̀ ọkùnrin ẹni ó fi ̀rẹ̀ wéwu?" Nítorí wọ́n fi ̀wọn wéwu láti padà , Dafidi mu ú.

Nǹkan wọ̀nyí ni àwọn akọni mẹ́ta ọkùnrin náà ṣe ohun ìyanu ńlá.

20 Abiṣai arákùnrin Joabu ìjòyè àwọn mẹ́ta. Ó gbé ̀kọ̀ rẹ̀ sókè lórí àwọn ̀́dúnrún (300) àwọn ènìyàn, àwọn ẹni ó pa, bẹ́̀ ni ó di olókìkí gẹ́gẹ́ àwọn mẹ́ta. 21 Ó gba ìlọ́po ọlá lórí àwọn mẹ́tẹ̀̀ta ó di olórí wọn, ó tilẹ̀ jẹ́ a ka kún ara wọn.

22 Benaiah ọmọ Jehoiada ó jẹ́ akọni oníjà láti Kabṣeeli, ẹni ó ṣe iṣẹ́ agbára ńlá. Ó pa àwọn ọmọ Arieli méjì ti Moabu, ó tún sọ̀kalẹ̀ lọ inú ihò lákokò yìnyín dídì, ó pa kìnnìún kan 23 Ó pa ara Ejibiti ẹni ó ga ìwọ̀n ẹsẹ̀ méje àti ààbọ̀ ṣùgbọ́n àwọn ará Ejibiti wọn ̀kọ̀ gẹ́gẹ́ ìdábùú igi ahunṣọ àti ̀ọwọ́ rẹ̀, Benaiah sọ̀kalẹ̀ lórí rẹ̀ pẹ̀kùmọ̀. Ó gba ̀kọ̀ náà láti ọwọ́ ará Ejibiti ó pa á pẹ̀̀kọ̀ rẹ̀. 24 Nǹkan wọ̀nyí ìwà akin Benaiah ọmọ Jehoiada; ohun náà pẹ̀di olókìkí gẹ́gẹ́ àwọn akọni ọkùnrin mẹ́ta. 25 Ó ọlá púpọ̀ ju àwọn ọgbọ̀n lọ, ṣùgbọ́n a á láàrín àwọn mẹ́tẹ̀̀ta. Dafidi fi ìkáwọ́ àwọn ̀ṣọ́.

26 Àwọn akọni ọkùnrin náà nìyí:

Asaheli arákùnrin Joabu,

Elhanani ọmọ Dodo láti Bẹtilẹhẹmu,

27 Ṣamotu ará Harori,

Helesi ará Peloni

28 Ira ọmọ Ikẹsi láti Tekoa,

Abieseri láti Anatoti,

29 Sibekai ará Huṣati,

láti ará Ahohi

30 Maharai ará Netofa,

Heledi ọmọ Baanah ará Netofa,

31 Itai ọmọ Ribai láti Gibeah Benjamini,

Benaiah ará Piratoni,

32 Hurai láti àfonífojì Gaaṣi,

Abieli ará Arbati,

33 Asmafeti ará Bahurimu

Eliaba ará Ṣaalboni.

34 Àwọn ọmọ Haṣemu ará Gisoni

Jonatani ọmọ Ṣage ará Harari.

35 Ahiamu ọmọ Sakari ará Harari,

Elifali ọmọ Uri

36 Heferi ará Mekerati,

Ahijah ará Peloni,

37 Hesro ará Karmeli

Naarai ọmọ Esbai,

38 Joẹli arákùnrin Natani

Mibari ọmọ Hagari,

39 Seleki ará Ammoni,

Naharai ará Beroti ẹni ó jẹ́ ẹni n ru ìhámọ́ra Joabu ọmọ Seruiah.

40 Ira ará Itri,

Garebu ará Itri,

41 Uriah ará Hiti

Sabadi ọmọ Ahlai.

42 Adina ọmọ Ṣisa ará Reubeni, ẹni ó jẹ́ ìjòyè ará Reubeni, àti pẹ̀ọgbọ́n rẹ̀.

43 Hanani ọmọ Maaka.

Jehoṣafati ará Mitini.

44 Ussia ará Asiterati,

Ṣama àti Jeieli àwọn ọmọ Hotami ará Aroeri,

45 Jediaeli ọmọ Ṣimri,

àti arákùnrin Joha ará Tisi

46 Elieli ará Mahafi

Jeribai àti Joṣafia àwọn ọmọ Elnaamu,

Itimah ará Moabu,

47 Elieli, Obedi àti Jaasieli ará Mesoba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também