Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 8

Israẹli béèrè fún ọba

1 Nígbà Samuẹli di arúgbó, ó yan àwọn ọmọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ adájọ́ fún Israẹli. 2 Orúkọ àkọ́rẹ̀ a máa jẹ́ Joẹli àti orúkọ èkejì a máa jẹ́ Abijah, wọ́n ṣe ìdájọ́ Beerṣeba. 3 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ rẹ̀, rìn ̀rẹ̀. Wọ́n yípadà èrè àìṣòótọ́, wọ́n gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀, wọ́n ń ìdájọ́ po.

4 Bẹ́̀ ni, gbogbo àwọn àgbàgbà ti Israẹli péjọpọ̀, wọ́n sọ́dọ̀ Samuẹli Rama. 5 Wọ́n fún un , "Ìwọ ti di arúgbó, àwọn ọmọ rẹ rìn ̀rẹ, nísinsin yìí, yan ọba fún wa ó máa darí wa gẹ́gẹ́ i gbogbo orílẹ̀-èdè."

6 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n , "Fún wa ọba yóò darí wa," èyí tẹ́ Samuẹli lọ́rùn, ó gbàdúrà Olúwa. 7 Olúwa sọ fún Samuẹli , "Gbọ́ ohùn àwọn ènìyàn náà, gbogbo èyí wọ́n sọ fún ; nítorí í ṣe ìwọ ni wọ́n kọ̀, ṣùgbọ́n èmi ni wọ́n kọ̀ gẹ́gẹ́ ọba lórí wọn. 8 Gẹ́gẹ́ wọ́n ti ṣe ọjọ́ mo wọn jáde láti Ejibiti títí di ọjọ́ òní, wọ́n kọ̀ sílẹ̀, wọ́n ń sin ọlọ́run mìíràn, bẹ́̀ ni wọ́n ń ṣe . 9 Nísinsin yìí, gbọ́ tiwọn; ṣùgbọ́n kìlọ̀ fún wọn dáradára, o jẹ́ wọ́n mọ irú ohun ọba yóò jẹ́ lórí wọn yóò ṣe."

10 Samuẹli sọ gbogbo ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ ènìyàn ó ń béèrè fún ọba lọ́wọ́ rẹ̀. 11 Ó , "Èyí ni ohun ọba yóò jẹ lórí yín yóò ṣe. Yóò àwọn ọmọkùnrin yín, yóò wọn ṣiṣẹ́ pẹ̀àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ àti fún ẹlẹ́ṣin rẹ, wọn yóò máa sáré níwájú kẹ̀kẹ́ rẹ̀. 12 Yóò yan díẹ̀ láti jẹ́ olórí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti olórí àádọ́ta àti àwọn mìíràn. Yóò yan wọ́n láti máa tulẹ̀ oko rẹ̀ àti láti máa kórè rẹ̀ àti àwọn mìíràn láti máa ṣe ohun èlò ogun àti ohun èlò kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀. 13 Yóò àwọn ọmọbìnrin yín láti máa ṣe olùṣe ìkunra olóòórùn dídùn àti láti máa ṣe àsè àti láti máa ṣe àkàrà. 14 Yóò èyí ó dára nínú oko yín, àti nínú ọgbà àjàrà yín àti nínú igi olifi yín, yóò fi wọ́n fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀. 15 Yóò ìdásímẹ́wàá hóró ọkà yín àti àká èso àjàrà yín, yóò fi fún àwọn oníṣẹ́ àti ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀. 16 Àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin yín àti èyí ó dára nínú ẹran ̀sìn àti àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ yín ni yóò fún ìlò ti ara rẹ̀. 17 Yóò ìdámẹ́wàá nínú àwọn agbo ẹran yín, yóò máa ṣe ẹrú u rẹ̀. 18 ọjọ́ náà , ̀yin yóò kígbe fún ìrànlọ́wọ́ láti ̀dọ̀ ọba ̀yin ti yàn. Olúwa a yín lóhùn ọjọ́ náà."

19 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà kọ̀ láti tẹ́Samuẹli wọ́n , "Rárá! A ìwọ fẹ́ jẹ́ ọba lórí i wa? 20 Nígbà náà àwa yóò dàbí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, pẹ̀ọba láti darí i wa àti láti jáde lọ níwájú wa láti ja ogun wa."

21 Nígbà Samuẹli gbọ́ gbogbo ohun àwọn ènìyàn sọ, ó tún tún un sọ níwájú Olúwa. 22 Olúwa dáhùn , "Tẹ́wọn, o yan ọba fún wọn."

Nígbà náà, Samuẹli sọ fún àwọn ọkùnrin Israẹli , "olúkúlùkù padà ìlú u rẹ̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também