Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 14

1 ọjọ́ kan, Jonatani ọmọ Saulu fún ̀dọ́mọkùnrin ó ń ru ìhámọ́ra rẹ̀ , ", jẹ́ a rékọjá lọ ìlú olódi àwọn Filistini ó ìhà kejì." Ṣùgbọ́n sọ fún baba rẹ̀.

2 Saulu dúró ìhà etí ìpínlẹ̀ Gibeah lábẹ́ igi pomegiranate èyí ó Migroni. Àwọn ẹgbẹ̀ta (600) ọkùnrin pẹ̀rẹ̀, 3 lára wọn ni Ahijah, ó wọ efodu. Òun ni ọmọ arákùnrin Ikabodu Ahitubu, ọmọ Finehasi, ọmọ Eli, àlùfáà Olúwa Ṣilo ẹni ó mọ̀ Jonatani ti lọ.

4 ̀Jonatani ti ń fẹ́ láti kọjá ìlú olódi àwọn Filistini, bèbè òkúta mímú kan , orúkọ èkínní ń jẹ́ Bosesi, orúkọ èkejì ń jẹ́ Sene. 5 Bèbè òkúta kan dúró àríwá ìhà Mikmasi, èkejì gúúsù ìhà Gibeah.

6 Jonatani fún ̀dọ́mọkùnrin ó ń ru ìhámọ́ra rẹ̀ , ", jẹ́ a lọ ìlú olódi àwọn aláìkọlà yìí. Bóyá Olúwa yóò fún wa, ohun di Olúwa lọ́wọ́ láti gbàlà, yálà nípasẹ̀ púpọ̀ tàbí nípasẹ̀ díẹ̀."

7 Ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀ , "Ṣe gbogbo ohun ó ọkàn rẹ, tẹ̀síwájú, Èmi pẹ̀ọkàn àti ̀rẹ."

8 Jonatani , "nígbà náà, àwa yóò rékọjá ̀dọ̀ ọkùnrin wọ̀nyí, a jẹ́ wọ́n wa. 9 wọ́n sọ fún wa , dúró títí àwa yóò fi tọ̀ yín ,àwa yóò dúró ibi a , àwa yóò gòkè tọ̀ wọ́n lọ. 10 Ṣùgbọ́n wọ́n , gòkè tọ̀ ,àwa yóò gòkè lọ, nítorí èyí ni yóò jẹ́ àmì fún wa Olúwa ti fi wọ́n wa lọ́wọ́."

11 Báyìí àwọn méjèèjì fi ara wọn hàn fún ìlú olódi Filistini. Àwọn Filistini , "ó! Àwọn Heberu ń yọ jáde láti inú ihò wọ́n fi ara wọn pamọ́ ." 12 Àwọn ọkùnrin ìlú olódi náà kígbe Jonatani àti ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀ , "gòkè tọ̀ àwa yóò kọ́ yín ̀kọ́."

Jonatani fún ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀ , "Gòkè tọ̀ lẹ́yìn; Olúwa ti fi wọ́n Israẹli lọ́wọ́."

13 Jonatani lo ọwọ́ àti ẹsẹ̀ rẹ̀ láti gòkè pẹ̀ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀ ọwọ́ ̀tún ̀gbẹ́ rẹ̀. Àwọn Filistini ṣubú níwájú Jonatani ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀ tẹ̀e, ó ń pa lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀. 14 ìkọlù èkínní yìí, Jonatani àti ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀ pa ogún ọkùnrin agbègbè ìwọ̀n ààbọ̀ sáré ilẹ̀.

15 Nígbà náà ni ìbẹ̀rùbojo àwọn ọmọ-ogun; àwọn ó ibùdó àti pápá, àti àwọn ó ilé ìlú olódi àti àwọn ń ìkógun, ilẹ̀ . Ó jẹ́ ìbẹ̀ó ti ̀dọ̀ Ọlọ́run .

Àwọn ogun Filistini àsálà

16 Àwọn ó ń ṣọ́fún Saulu Gibeah ti Benjamini àwọn ọmọ-ogun ń túká gbogbo ̀. 17 Nígbà náà ni Saulu fún àwọn ènìyàn ó pẹ̀rẹ̀ , "ka àwọn ènìyàn mọ ẹni ó jáde kúrò nínú wa." Nígbà wọ́n ṣe bẹ́̀, ó, Jonatani àti ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀ ni níbẹ̀.

18 Saulu fún Ahijah , "Gbé àpótí Ọlọ́run ." Àpótí Ọlọ́run pẹ̀àwọn ọmọ Israẹli ìgbà náà. 19 Nígbà Saulu ń àlùfáà sọ̀rọ̀, ariwo ibùdó àwọn Filistini ń pọ̀ síwájú . Saulu fún àlùfáà , "ọwọ́ rẹ dúró."

20 Saulu àti gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ péjọ, wọ́n lọ ojú ìjà. Wọ́n gbogbo àwọn Filistini ìdàrúdàpọ̀ ńlá, idà olúkúlùkù lára ọmọ ẹnìkejì rẹ̀. 21 Àwọn Heberu ó ti lọ́dọ̀ àwọn Filistini tẹ́lẹ̀, wọ́n ti gòkè tẹ̀wọn lọ àgọ́ wọn sọ́dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli wọ́n ti pẹ̀Saulu àti Jonatani. 22 Nígbà gbogbo àwọn Israẹli ó ti pa ara wọn mọ́ nínú òkè ńlá Efraimu gbọ́ àwọn Filistini , wọ́n darapọ̀ mọ́ ìjà náà ìlépa gbígbóná. 23 Bẹ́̀ ni Olúwa gba Israẹli ọjọ́ náà, ìjà náà rékọjá Beti-Afeni.

Jonatani jẹ oyin

24 Gbogbo ọkùnrin Israẹli ìpọ́njú ńlá ọjọ́ náà, nítorí Saulu ti fi àwọn ènìyàn gégùn ún , "Ègbé ni fún ẹni ó jẹ oúnjẹ títí di alẹ́, títí èmi yóò fi gbẹ̀san mi lára àwọn ̀mi!" Bẹ́̀ ni ẹnìkankan nínú ̀wọ́ ogun náà ó fi ẹnu kan oúnjẹ.

25 Gbogbo àwọn ènìyàn wọ inú igbó, oyin lórí ilẹ̀ náà. 26 Nígbà wọ́n inú igbó náà, wọ́n oyin ń sun jáde, ẹni ó fi ọwọ́ rẹ̀ kan ẹnu rẹ̀ síbẹ̀, nítorí wọ́n bẹ̀ìfiré. 27 Ṣùgbọ́n Jonatani gbọ́ baba rẹ̀ ti fi ìfibú kìlọ̀ fún àwọn ènìyàn náà, bẹ́̀ ni ó tẹ orí ̀ń bẹ ọwọ́ rẹ̀ bọ afárá oyin náà, ó fi ẹnu rẹ̀, ojú rẹ̀ dán. 28 Nígbà náà ni ̀kan nínú àwọn ọmọ-ogun sọ fún un , "Baba rẹ fi ìfibú kìlọ̀ fún àwọn ọmọ-ogun , Ègbé ni fún ẹni ó jẹ oúnjẹ òní!Ìdí nìyìí àárẹ̀ fi àwọn ènìyàn."

29 Jonatani , "Baba mi ti ìdààmú ìlú, ó ojú mi ti dán nígbà mo fi ẹnu kan oyin yìí. 30 Báwo ni ti dára àwọn ènìyàn ti jẹ nínú ìkógun àwọn ̀wọn lónìí, pípa àwọn Filistini ìbá ti pọ̀ ?"

31 ọjọ́ náà, lẹ́yìn ìgbà àwọn ọmọ Israẹli ti pa nínú àwọn Filistini láti Mikmasi Aijaloni, ó rẹ àwọn ènìyàn náà. 32 Wọ́n sáré ìkógun náà, wọ́n àgùntàn. Màlúù àti ọmọ màlúù, wọ́n pa wọ́n sórí ilẹ̀, wọ́n jẹ wọ́n papọ̀ tẹ̀jẹ́tẹ̀jẹ̀. 33 Nígbà náà ni ẹnìkan fún Saulu , "ó, àwọn ènìyàn ń dẹ́ṣẹ̀ Olúwa nípa jíjẹ ẹran ó ̀jẹ̀ lára."

Ó , "̀ṣẹ̀ yín ti pọ̀, òkúta ńlá ibi nísinsin yìí." 34 Nígbà náà ni ó , "jáde lọ sáàrín àwọn ènìyàn náà fún wọn , olúkúlùkù wọn màlúù àti àgùntàn tirẹ̀ tọ̀ , wọ́n pa wọ́n níhìn-ín, wọ́n jẹ́. ṣe ṣẹ̀ Olúwa, ṣe jẹ ẹran tòun-tẹ̀jẹ̀.’ "

Bẹ́̀ olúkúlùkù màlúù tirẹ̀ alẹ́ ọjọ́ náà, wọ́n pa wọ́n níbẹ̀. 35 Nígbà náà Saulu kọ́ pẹpẹ kan fún Olúwa; èyí jẹ́ ìgbà àkọ́kọ́ ó kọ́kọ́ ṣe èyí.

36 Saulu , "jẹ́ a sọ̀kalẹ̀ tọ Filistini lọ òru, a wọn títí di ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀, a ṣì ṣe ẹnìkankan nínú wọn."

Wọ́n , "Ṣe ohun ó dára ojú rẹ̀."

Ṣùgbọ́n àlùfáà , "jẹ́ a ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Ọlọ́run níhìn-ín."

37 Nígbà náà ni Saulu béèrè lọ́dọ̀ Ọlọ́run , "Ṣé n sọ̀kalẹ̀ tọ àwọn Filistini lọ ? Ǹjẹ́ ìwọ yóò fi wọ́n Israẹli lọ́wọ́ ?" Ṣùgbọ́n Ọlọ́run a lóhùn ọjọ́ náà.

38 Saulu , "síyìn-ín ín, gbogbo ̀yin jẹ́ olórí ogun, a ṣe ìwádìí irú ̀ṣẹ̀ ti ṣẹ̀ lónìí. 39 Olúwa ó gba Israẹli ti , ó ṣe a í lára Jonatani ọmọ mi, ó láti ." Ṣùgbọ́n ẹnìkankan nínú wọn sọ ̀rọ̀ kan.

40 Nígbà náà ni Saulu fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli , "lọ apá kan; èmi àti Jonatani ọmọ mi yóò lọ apá kan."

Gbogbo àwọn ènìyàn dáhùn , "Ṣe èyí ó tọ́ ojú rẹ."

41 Nígbà náà ni Saulu gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run Israẹli , "Fún mi ìdáhùn ó tọ́." A Jonatani àti Saulu nípa ìbò dídì, àwọn ènìyàn náà yege. 42 Saulu , "dìbò láàrín èmi àti Jonatani ọmọ mi." Ìbò náà Jonatani.

43 Saulu fún Jonatani , "Sọ nǹkan ìwọ ṣe fún mi."

Jonatani sọ fún un , "Mo kàn fi orí ̀mi tọ́ oyin díẹ̀ . Nísinsin yìí ṣé mo láti ?"

44 Saulu , "Ọlọ́run ó ṣe bẹ́̀ àti bẹ́̀ lọ mi, nítorí ìwọ Jonatani yóò à dandan."

45 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn fún Saulu , "Ǹjẹ́ ó yẹ Jonatani , ẹni ó ti ìgbàlà ńlá yìí fún Israẹli? a í! Olúwa ti , ̀kan nínú irun orí rẹ̀ yóò bọ́ sílẹ̀, nítorí ó ṣe èyí pẹ̀ìrànlọ́wọ́." Báyìí ni àwọn ènìyàn gba Jonatani sílẹ̀, .

46 Nígbà náà ni Saulu dẹ́kun lílépa àwọn Filistini, àwọn Filistini padà ìlú wọn.

47 Lẹ́yìn ìgbà Saulu ti jẹ ọba lórí Israẹli, ó gbogbo ̀wọn yíká: Moabu àti àwọn ọmọ Ammoni; Edomu, àti àwọn ọba Soba, àti àwọn Filistini. Ibikíbi ó kọjú , ó máa ń fi ìyà jẹ wọ́n. 48 Ó tagbára tagbára, ó ṣẹ́gun àwọn Amaleki, ó ń gba Israẹli sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ó ń kọlù wọ́n.

Ìdílé Saulu

49 14.49: 1Sa 31.2; 1Ki 10.2. Àwọn ọmọ Saulu ni Jonatani, Iṣifi àti Malikiṣua. Orúkọ ọmọbìnrin rẹ̀ àgbà ni Merabu àti orúkọ ọmọbìnrin rẹ̀ kékeré ni Mikali. 50 Orúkọ ìyàwó rẹ̀ Ahinoamu ọmọbìnrin Ahimasi. Orúkọ olórí ogun rẹ̀ ni Abneri ọmọ Neri arákùnrin baba Saulu. 51 Kiṣi baba Saulu àti Neri baba Abneri wọ́n jẹ́ ọmọ Abieli.

52 gbogbo ọjọ́ Saulu, ogun náà gbóná àwọn Filistini, níbikíbi Saulu ti alágbára tàbí akíkanjú ọkùnrin, a u láti máa a ṣiṣẹ́.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também