Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 12

̀rọ̀ ìdágbére Samuẹli

1 Samuẹli fún gbogbo Israẹli , "Èmi gbọ́ gbogbo ohun sọ fún mi, èmi ti yan ọba fún un yín. 2 Nísinsin yìí ti ọba olórí yín. ó ṣe tèmi, èmi ti di arúgbó, mo ti hewú, àwọn ọmọ mi ń bẹ níhìn-ín yìí pẹ̀yín. Èmi ti ń ṣe olórí yín láti ìgbà èwe mi títí di òní yìí. 3 Èmi dúró níhìn-ín yìí, jẹ́rìí mi níwájú Olúwa àti níwájú ẹni àmì òróró rẹ̀. Màlúù ta ni mo gbà ? Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ta ni mo gbà ? Ta ni mo rẹ́ jẹ ? Ọwọ́ ta ni mo ti gba owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ kan láti fi bo ara mi lójú? mo ti ṣe nǹkan kan nínú ohun wọ̀nyí, èmi yóò san án padà fún yín."

4 Wọ́n dáhùn , "Ìwọ rẹ́ wa jẹ tàbí pọ́n wa lójú , ìwọ gba ohunkóhun lọ́wọ́ ẹnìkankan."

5 Samuẹli fún wọn , "Olúwa ni ẹlẹ́rìí i yín, àti ẹni àmì òróró rẹ̀ ni ẹlẹ́rìí lónìí , ̀yin ohunkóhun lọ́wọ́ mi."

Wọ́n sọ , "Òun ni ẹlẹ́rìí."

6 Nígbà náà ni Samuẹli fún àwọn ènìyàn náà , "Olúwa ni ó yan Mose àti Aaroni àti ti ó àwọn baba ńlá yín gòkè láti Ejibiti. 7 Nísinsin yìí, dúró níbi, nítorí èmi ń lọ láti a yín sọ̀rọ̀ níwájú Olúwa ti gbogbo ìṣe òdodo rẹ̀ ó ti ṣe fún un yín àti fún àwọn baba yín.

8 "Lẹ́yìn ìgbà Jakọbu wọ Ejibiti, wọ́n pe Olúwa fún ìrànlọ́wọ́, Olúwa rán Mose àti Aaroni, wọ́n àwọn baba ńlá yín jáde láti Ejibiti láti wọn jókòó níbí yìí.

9 "Ṣùgbọ́n wọ́n gbàgbé Olúwa Ọlọ́run wọn; bẹ́̀ ni wọ́n wọ́n ọwọ́ àwọn Sisera, olórí ogun Hasori, àti ọwọ́ àwọn Filistini àti ọwọ́ ọba Moabu, ó wọn . 10 Wọ́n kégbe pe Olúwa, wọ́n , Àwa ti ṣẹ̀; a ti kọ Olúwa sílẹ̀, a ti sin Baali, àti Aṣtoreti. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí gbà lọ́wọ́ àwọn ̀wa, àwa yóò sìn ́.’ 11 Nígbà náà ni Olúwa rán Jerubbaali, Bedani, Jefta àti Samuẹli, ó gbà yín lọ́wọ́ àwọn ̀a yín gbogbo, bẹ́̀ ni ̀yin ń gbé àlàáfíà.

12 "Ṣùgbọ́n nígbà ̀yin i Nahaṣi ọba àwọn Ammoni dìde i yín, sọ fún mi , Rárá, àwa ń fẹ́ ọba yóò jẹ́ lórí wa,ó tilẹ̀ jẹ́ Olúwa Ọlọ́run yín jẹ́ ọba yín. 13 Nísinsin yìí èyí ni ọba ̀yin ti yàn, ̀yin béèrè fún; ó, Olúwa ti fi ọba jẹ lórí yín. 14 ̀yin bẹ̀Olúwa àti ̀yin ń sìn ín, gbọ́ tirẹ̀, ̀yin ṣọ̀tẹ̀ àṣẹ rẹ̀, àti ̀yin àti ọba ó jẹ lórí yín ń tẹ̀Olúwa Ọlọ́run yín: ó dára 15 ṣùgbọ́n ̀yin gbọ́ Olúwa, ṣọ̀tẹ̀ àṣẹ rẹ̀, ọwọ́ rẹ̀ yóò lára yín ibi, ó ti lára baba yín.

16 "Nítorí náà, dúró jẹ́́ wo ohun ńlá yìí Olúwa fẹ́ ṣe ojú u yín! 17 Òní í ha á ṣe ọjọ́ ìkórè ọkà alikama ? Èmi yóò pe Olúwa ó rán àrá àti òjò. ̀yin yóò mọ irú ohun búburú ti ṣe níwájú Olúwa nígbà ̀ ń béèrè fún ọba."

18 Nígbà náà ni Samuẹli pe Olúwa, Olúwa rán àrá àti òjò ọjọ́ náà. Bẹ́̀ ni gbogbo ènìyàn bẹ̀Olúwa àti Samuẹli púpọ̀.

19 Gbogbo àwọn ènìyàn fún Samuẹli , "Gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run rẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ a ba à , nítorí àwa ti fi búburú yìí kún ̀ṣẹ̀ wa bíbéèrè fún ọba."

20 Samuẹli wọn lóhùn , "bẹ̀, ti ṣe gbogbo búburú yìí; síbẹ̀ ṣe yípadà kúrò lọ́dọ̀ Olúwa, ṣùgbọ́n fi gbogbo àyà yín sin Olúwa. 21 ṣe yípadà sọ́dọ̀ àwọn òrìṣà. Wọn le ṣe ohun rere kan fún un yín, tàbí wọ́n gbà yín , nítorí asán ni wọ́n. 22 Nítorí orúkọ ńlá rẹ̀ Olúwa yóò kọ àwọn ènìyàn rẹ̀ sílẹ̀, nítorí inú Olúwa dùn láti fi yín ṣe ènìyàn rẹ̀. 23 ó ṣe ti èmi ni, á i èmi dẹ́ṣẹ̀ Olúwa nípa dídẹ́kun àti gbàdúrà fún un yín. Èmi yóò kọ́ yín ̀rere àti ̀òtítọ́. 24 Ṣùgbọ́n i dájú , bẹ̀Olúwa, sìn ín nínú òtítọ́ pẹ̀gbogbo ọkàn an yín, kíyèsi ohun ńlá ó ti ṣe fún un yín. 25 Síbẹ̀ ̀yin ń ṣe búburú, ̀yin àti ọba yín ni a ó gbá kúrò."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também