Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 23

Dafidi gbà Keila lọ́wọ́ àwọn Filistini

1 Wọ́n fún Dafidi , "ó, àwọn ará Filistini ń ará Keila jagun, wọ́n ja àwọn ilẹ̀ ìpakà lólè." 2 Dafidi béèrè lọ́dọ̀ Olúwa , "Ṣé èmi ó lọ kọlu àwọn ará Filistini wọ̀nyí ?"

Olúwa fún Dafidi , "Lọ o kọlu àwọn ará Filistini o gba Keila sílẹ̀."

3 Àwọn ọmọkùnrin ó lọ́dọ̀ Dafidi fún un , "ó, àwa ń bẹ̀níhìn-ín yìí Juda; ǹjẹ́ yóò ti nígbà ti àwa Keila láti fi ojú ko ogun àwọn ara Filistini?"

4 Dafidi tún béèrè lọ́dọ̀ Olúwa. Olúwa a lóhùn, ó , "Dìde, o sọ̀kalẹ̀ lọ Keila, nítorí èmi ó fi àwọn ará Filistini náà lọ́wọ́." 5 Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ lọ Keila, wọ́n àwọn ará Filistini , wọ́n ohun ̀sìn wọn, wọ́n fi ìparun ńlá pa wọ́n. Dafidi gba àwọn ará Keila sílẹ̀. 6 Ó ṣe, nígbà Abiatari ọmọ Ahimeleki fi tọ Dafidi lọ Keila, ó sọ̀kalẹ̀ òun pẹ̀efodu kan lọ́wọ́ rẹ̀.

7 A sọ fún Saulu Dafidi Keila. Saulu , "Ọlọ́run ti fi í mi lọ́wọ́; nítorí ó ti ara rẹ̀ mọ́ ti wíwá ó ìlú ó ìlẹ̀kùn àti kẹrẹ." 8 Saulu pe gbogbo àwọn ènìyàn náà jọ ogun, láti sọ̀kalẹ̀ lọ Keila, láti Dafidi mọ́ àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀.

9 Dafidi mọ̀ Saulu ti gbèrò búburú òun; ó fún Abiatari àlùfáà náà , "efodu náà níhìn-ín yìí!" 10 Dafidi , "Olúwa Ọlọ́run Israẹli, lóòótọ́ ni ìránṣẹ́ rẹ ti gbọ́ Saulu ń ̀láti Keila, láti fọ́ ìlú náà nítorí mi. 11 Àwọn àgbà ìlú Keila yóò fi e lọ́wọ́ ? Saulu yóò ha sọ̀kalẹ̀, gẹ́gẹ́ ìránṣẹ́ rẹ ti gbọ́ ?"

Olúwa Ọlọ́run Israẹli, èmi bẹ̀ ́, fún ìránṣẹ́ rẹ. Olúwa , "Yóò sọ̀kalẹ̀ ."

12 Dafidi , "Àwọn àgbà ìlú Keila yóò fi èmi àti àwọn ọmọkùnrin mi Saulu lọ́wọ́ ?"

Olúwa , "Wọn ó fi ́ wọn lọ́wọ́."

13 Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ wọ́n ẹgbẹ̀ta (600) ènìyàn dìde, wọ́n lọ kúrò Keila, wọ́n lọ ibikíbi wọ́n rìn lọ. A fún Saulu , "Dafidi ti kúrò Keila; lọ Keila mọ́."

14 Dafidi ń gbé aginjù, níbi ó ti pamọ́ , ó ń gbé níbi òkè ńlá kan aginjù Sifi. Saulu ń a lójoojúmọ́, ṣùgbọ́n Ọlọ́run fi e lọ́wọ́.

Àwọn ará Sifi dalẹ̀ Dafidi

15 Nígbà Dafidi Horeṣi aginjù Sifi, Dafidi i , Saulu ti jáde láti ̀òun kiri. 16 Jonatani ọmọ Saulu dìde, ó tọ Dafidi lọ nínú igbó Horeṣi, ó gbà á ìyànjú nípa ti Ọlọ́run. 17 Òun fún un , "ṣe bẹ̀, nítorí ọwọ́ Saulu baba mi yóò tẹ̀ ́. Ìwọ ni yóò jẹ ọba lórí Israẹli, èmi ni yóò ṣe ibìkejì rẹ. Saulu baba mi mọ̀ bẹ́̀ pẹ̀." 18 Àwọn méjèèjì ṣe àdéhùn níwájú Olúwa; Dafidi jókòó nínú igbó Horeṣi. Jonatani lọ ilé rẹ̀.

19 Àwọn ará Sifi gòkè tọ Saulu Gibeah, wọ́n , "Ṣé Dafidi ti fi ara rẹ̀ pamọ́ sọ́dọ̀ wa ibi gíga ìsápamọ́Horeṣi, òkè Hakila, ó níhà gúúsù ti Jeṣimoni. 20 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ọba, sọ̀kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bi gbogbo ìfẹ́ ó ọkàn rẹ láti sọ̀kalẹ̀: ipa àwa láti fi ọba lọ́wọ́."

21 Saulu , "Alábùkún fún ni ̀yin nípa Olúwa; nítorí ̀yin ti káàánú fún mi. 22 Lọ, èmi bẹ̀ yín, tún múra, mọ̀ ki si ibi ẹsẹ̀ rẹ̀ gbé , àti ẹni ó níbẹ̀: nítorí a ti sọ fún mi , ọgbọ́n ni ó ń jọjọ. 23 , mọ ibi ìsápamọ́ ó máa ń pamọ́ , tún padà tọ̀ , èmi mọ̀ dájú; èmi ó yín lọ: yóò ṣe ó ilẹ̀ Israẹli, èmi ó a àwárí nínú gbogbo ẹgbẹ̀rún Juda!"

24 Wọ́n dìde, wọ́n ṣáájú Saulu lọ Sifi, ṣùgbọ́n Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ aginjù Maoni, pẹ̀tẹ́lẹ̀ níhà gúúsù ti Jeṣimoni. 25 Saulu àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ lọ ń a. Wọ́n sọ fún Dafidi: ó sọ̀kalẹ̀ ibi òkúta kan, ó jókòó aginjù ti Maoni. Saulu gbọ́, ó lépa Dafidi aginjù Maoni.

26 Saulu ń rin apá kan òkè kan, Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ apá kejì òkè náà. Dafidi yára láti kúrò níwájú Saulu; nítorí Saulu àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ ti rọ̀gbà Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ láti wọn. 27 Ṣùgbọ́n oníṣẹ́ kan tọ Saulu ó , "Ìwọ yára o , nítorí àwọn Filistini ti gbé ogun ti ilẹ̀ wa." 28 Saulu padà kúrò lílépa Dafidi, ó lọ pàdé àwọn Filistini nítorí náà ni wọ́n ṣe ń pe ibẹ̀ náà Selahamalekoti (èyí ó túmọ̀ "Òkúta Ìpinyà"). 29 Dafidi gòkè láti ibẹ̀ lọ, ó jókòó níbi ó pamọ́ En-Gedi.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também