Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 9

1 9.1,2: Es 2.70; Ne 7.73; 11.3. Gbogbo Israẹli ni a kọ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ̀dọ̀ àwọn baba ńlá nínú ìwé àwọn ọba Israẹli. Àwọn ènìyàn Juda ni a ìgbèkùn lọ Babeli nítorí àìṣòótọ́ wọn.

Àwọn ènìyàn ó Jerusalẹmu

2 Nísinsin yìí, àwọn ó kọ́kọ́ tún tẹ̀lórí ohun ìní wọn ìlú wọn ni díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa.

3 9.3-17: Ne 11.4-19. Àwọn ó láti Juda láti Benjamini àti láti Efraimu àti Manase ó ń gbé Jerusalẹmu jẹ́:

4 Uttai ọmọ Ammihudu, ọmọ Omri, ọmọ Imri, ọmọ Bani, ìran ọmọ Peresi ọmọ Juda.

5 Àti nínú ará Ṣilo:

Asaiah àkọ́àti àwọn ọmọ rẹ̀.

6 ti ará Sera:

Jeueli.

Àwọn ènìyàn láti Juda jẹ́ ̀́dẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́wàá (690).

7 Àti nínú àwọn ọmọ Benjamini ni:

Sallu ọmọ Meṣullamu, ọmọ Hodafiah; ọmọ Hasenuah;

8 Ibinaiah ọmọ Jerohamu;

Ela ọmọ Ussi, ọmọ Mikri;

àti Meṣullamu ọmọ Ṣefatia; ọmọ Reueli, ọmọ Ibinijah.

9 Àwọn ènìyàn láti Benjamini gẹ́gẹ́ a ti ṣe kọ ́ nínú ìran wọn nínú ìtàn ìdílé láti ̀dọ̀ baba ńlá wọn, ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó dín mẹ́rìnlélógójì (956). Gbogbo àwọn ọkùnrin jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé.

10 ti àwọn àlùfáà:

Jedaiah; Jehoiaribi; Jakini;

11 Asariah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, olórí ó ń bojútó ilé Ọlọ́run;

12 Adaiah ọmọ Jerohamu, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malkiah;

àti Masai ọmọ Adieli, ọmọ Jahisera, ọmọ Meṣullamu ọmọ Meṣilemiti, ọmọ Immeri.

13 Àwọn àlùfáà, wọ́n jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé, ó jẹ́ ẹgbẹ̀sán ó dín méjì (1,760). Wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin, wọ́n dúró fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú ilé Ọlọ́run.

14 ti àwọn ará Lefi:

Ṣemaiah ọmọ Haṣubu, ọmọ Asrikamu, ọmọ Haṣabiah ará Merari;

15 Bakibakari, Hereṣi, Galali àti Mattaniah, ọmọ Mika, ọmọ Sikri, ọmọ Asafu;

16 Obadiah ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni;

àti Berekiah ọmọ Asa, ọmọ Elkana, ó ń gbé nínú àwọn ìlú àwọn ará Netofa.

17 Àwọn olùtọ́ẹnu-ọ̀:

Ṣallumu, Akkubu, Talmoni, Ahimani àti arákùnrin wọn, Ṣalumu olóyè wọn, 18 ti ipò ìdúró ẹnu-ọ̀ọba apá ìhà ìlà-oòrùn títí di àkókò . Wọ̀nyí ni àwọn olùtọ́ẹnu-ọ̀ó jẹ́ ti ìpàgọ́ àwọn ará Lefi.

19 Ṣallumu ọmọ Kore ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora, àti àwọn olùtọ́ẹnu-ọ̀ẹlẹgbẹ́ rẹ̀. Láti ìdílé rẹ̀ (àwọn ará Korati) ni ó dúró fún ṣíṣọ́ ìloro ẹnu-ọ̀àgọ́ gẹ́gẹ́ baba wọn ti ń dúró fún ṣíṣọ́ àbáwọlé ibùgbé Olúwa.

20 ìgbà àkọ́kọ́ Finehasi ọmọ Eleasari jẹ́ olórí fún àwọn olùtọ́ẹnu-ọ̀, Olúwa pẹ̀rẹ̀.

21 Sekariah, ọmọ Meṣelemiah jẹ́ olùtọ́ẹnu-ọ̀àbáwọlé àgọ́ ibi ìpàdé.

22 Gbogbo rẹ̀ lápapọ̀, àwọn a yàn láti jẹ́ olùtọ́ẹnu-ọ̀àwọn ìloro jẹ́ igba ó méjìlá (212). A ka àwọn wọ̀nyí nípa ìdílé ìletò wọn.

Àwọn olùtọ́ẹnu-ọ̀ni a ti yàn ipò láti ̀dọ̀ Dafidi àti Samuẹli, aríran, nítorí òtítọ́ wọn. 23 Àwọn àti àwọn ọmọ wọn ni ó fún ṣíṣọ́ ẹnu-ọ̀ilé Olúwa ilé a àgọ́. 24 Àwọn olùtọ́ẹnu-ọ̀igun mẹ́rẹ̀̀rin: ìlà-oòrùn, ìwọ̀-oòrùn àríwá àti gúúsù. 25 Àwọn arákùnrin wọn àwọn ìletò wọn láti àkókò àkókò láti pín iṣẹ́ ìsìn wọn fún àkókò ọjọ́ méje. 26 Ṣùgbọ́n àwọn olórí alábojútó ẹnu-ọ̀mẹ́rẹ̀̀rin wọ́n jẹ́ ará Lefi ni a yàn fún àwọn iyàrá àti àwọn àpótí ìṣúra ilé Ọlọ́run. 27 Wọ́n á lo gbogbo òru dídúró ilé Ọlọ́run , nítorí wọ́n láti ṣọ́ , wọ́n àṣẹ kọ́kọ́rọ́ fún ṣíṣí i àràárọ̀.

28 Díẹ̀ ìdí ohun èlò à ń fún ìsìn ilé Ọlọ́run; wọn a máa á nígbà wọ́n gbé e wọlé àti nígbà a wọn jáde. 29 Àwọn mìíràn ni a yàn láti bojútó ohun èlò àti gbogbo ohun èlò ilé a sọ́tọ̀ fún Ọlọ́run, àti ìyẹ̀fun àti ọtí èso àjàrà àti òróró náà, tùràrí àti tùràrí olóòórùn dídùn. 30 Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú àwọn àlùfáà ni ó ń bojútó pípò tùràrí olóòórùn dídùn papọ̀. 31 Ará Lefi a sọ Mattitiah àkọ́ọmọkùnrin Ṣallumu ará Kora ni a yàn, ń ṣe alábojútó ohun a dín. 32 Àti nínú àwọn arákùnrin wọn, nínú àwọn ọmọ Kohati ń ṣe ìtọ́àkàrà ìfihàn, láti máa pèsè rẹ̀ ọjọọjọ́ ìsinmi.

33 Àwọn wọ́n jẹ́ ọkùnrin, olórí àwọn ìdílé Lefi dúró nínú àgọ́ ilé Olúwa, wọn ṣe lára iṣẹ́ ìsìn yòókù nítorí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ náà lọ́sàn, lóru.

34 Gbogbo wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn Lefi, olóyè gẹ́gẹ́ a ti ṣe kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé láti ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n ń gbé Jerusalẹmu.

Ìdílé àti Ìrandíran Saulu

35 Jeieli baba Gibeoni ń gbé Gibeoni.

Orúkọ ìyàwó rẹ̀ a máa jẹ́ Maaka, 36 pẹ̀àkọ́ọmọkùnrin rẹ̀ jẹ́ Abdoni, wọ̀nyí ń tẹ̀Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu. 37 Gedori, Ahio, Sekariah àti Mikiloti. 38 Mikiloti jẹ́ baba Ṣimeamu, àwọn náà ń gbé ̀ìbátan wọn Jerusalẹmu.

39 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba a Saulu, àti Saulu baba a Jonatani, àti Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.

40 Ọmọ Jonatani:

Meribu-Baali, ó jẹ́ baba Mika.

41 Àwọn ọmọ Mika:

Pitoni. Meleki, Tarea àti Ahasi.

42 Ahasi jẹ́ baba Jada, Jada jẹ́ baba Alemeti, Asmafeti, Simri, Simri jẹ́ baba Mosa. 43 Mosa jẹ́ baba Binea; Refaiah jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.

44 Aseli ọmọ mẹ́, pẹ̀wọ̀nyí ni orúkọ wọn:

Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli Ṣeariah, Obadiah àti Hanani, gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também