Pular para o conteúdo
Publicidade

Esteri 5

̀bẹ̀ Esteri ọba

1 ọjọ́ kẹta Esteri wọ aṣọ ayaba rẹ̀ ó dúró inú àgbàlá ààfin, iwájú gbọ̀ngàn ọba, ọba jókòó lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀ nínú gbọ̀ngàn, ó kọjú ẹnu-ọ̀ìta. 2 Nígbà ó ayaba Esteri ó dúró nínú àgbàlá, inú rẹ̀ yọ́ i, ọba na ̀aládé wúrà ọwọ́ rẹ̀ i. Bẹ́̀ ni Esteri ṣe súnmọ́ ọn ó fi ọwọ́ kan orí ̀náà.

3 5.3,6: Mk 6.23. Nígbà náà ni ọba béèrè , "ni ó , ayaba Esteri? ni o fẹ́? ó tilẹ̀ ṣe títí ìdajì ọba mi, àní, a ó fi fún ."

4 Esteri dáhùn , "ó tẹ́ ọba lọ́rùn, jẹ́ ọba, pẹ̀Hamani, lónìí ibi àsè èmi ti pèsè fún un."

5 Ọba , "Hamani kíákíá, nítorí a ṣe ohun Esteri béèrè fún un."

Bẹ́̀ ni ọba àti Hamani lọ ibi àsè Esteri ti pèsè. 6 wọ́n ṣe ń mu wáìnì, ọba tún béèrè lọ́wọ́ Esteri, "Báyìí : ni ̀bẹ̀ rẹ? A ó fi fún . ni ìwọ ń béèrè fún? Àní ó tilẹ̀ jẹ́ ìdajì ìjọba mi, a ó fi fún ."

7 Esteri dáhùn, "̀bẹ̀ mi àti ìbéèrè mi ni èyí. 8 ọba fi ojúrere rẹ̀ fún mi, ó tẹ́ ọba lọ́rùn láti gba ̀bẹ̀ mi àti láti ìbéèrè mi ṣẹ, jẹ́ ọba àti Hamani ̀la ibi àsè èmi yóò pèsè fún wọn. Nígbà náà ni èmi yóò dáhùn ìbéèrè ọba."

Ìrunú Hamani Mordekai

9 Hamani jáde lọ ọjọ́ náà pẹ̀ayọ̀ àti inú dídùn. Ṣùgbọ́n nígbà ó Mordekai ẹnu-ọ̀ọba, ó wòye dìde tàbí ó bẹ̀iwájú òun, inú i gidigidi Mordekai. 10 Ṣùgbọ́n, Hamani ara rẹ̀ ìjánu, ó lọ ilé.

Ó pe àwọn ̀rẹ́ rẹ̀ jọ àti Sereṣi ìyàwó rẹ̀ 11 Hamani gbéraga wọn nípa títóbi ̀rọ̀ rẹ̀, púpọ̀ àwọn ọmọ rẹ̀, àti gbogbo ̀ọba ti bu ọlá fún un àti ó ṣe gbé e ga ju àwọn ọlọ́àti àwọn ìjòyè tókù lọ. 12 Hamani tún fi kún un , "í ṣe èyí nìkan. Èmi nìkan ni ayaba Esteri láti sin ọba ibi àsè ó . Bákan náà, ó tún ti pẹ̀ọba ̀la. 13 Ṣùgbọ́n gbogbo èyí ì ì tẹ́ mi lọ́rùn níwọ̀n ìgbà mo ń Mordekai ará a Júù náà ó ń jókòó ẹnu-ọ̀ọba."

14 Ìyàwó rẹ̀ Sereṣi àti àwọn ̀rẹ́ rẹ̀ fún un , "Ri igi kan, ó ga ìwọ̀n ̀ṣẹ̀ bàtà márùn le láàdọ́rin, o sọ fún ọba òwúrọ̀ ̀la ó gbé Mordekai rọ̀ sórí i rẹ̀. Nígbà náà ni ìwọ yóò ọba lọ ibi àsè pẹ̀ayọ̀." Èrò dùn mọ́ Hamani nínú, ó ri igi náà.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também