Pular para o conteúdo
Publicidade

Esteri 1

A rọ ayaba Faṣti lóyè

1 Èyí ni ohun ṣẹlẹ̀ ìgbà Ahaswerusi, ó jẹ ọba lórí ̀tàdínláàdóje (127) ìletò bẹ̀rẹ̀ láti India títí ó fi Etiopia. 2 àkókò ìgbà náà ọba Ahaswerusi ń ṣe ìjọba orí ìtẹ́ rẹ̀ ilé ìṣọ́ ti Susa, 3 ọdún kẹta ìjọba rẹ̀, ó ṣe àsè fún gbogbo àwọn ọlọ́àti ìjòyè. Àwọn olórí ológun láti Persia àti Media, àwọn ọmọ-aládé, àti àwọn ọlọ́ìletò níbẹ̀ pẹ̀.

4 Ó ṣe àfihàn púpọ̀ ọrọ̀ ìjọba rẹ̀ àti dídán àti ògo ọláńlá rẹ̀ fún ọgọ́sàn-án ọjọ́ gbáko. 5 Nígbà ọjọ́ wọ̀nyí kọjá, ọba ṣe àsè fún ọjọ́ méje, nínú ọgbà ó nínú àgbàlá ààfin ọba, gbogbo ènìyàn láti orí ẹni ó kéré orí ẹni ó lọ́jùlọ, wọ́n ilé ìṣọ́ ti Susa. 6 Ọgbà náà aṣọ fèrèsé funfun àti aláwọ̀ òféfèé. Àwọn okùn a fi aṣọ aláwọ̀ funfun àti aláwọ̀ elése àlùkò rán ni a fi ta á mọ́ òrùka fàdákà lára àwọn òpó mabu. Àwọn ibùsùn a fi wúrà àti fàdákà ṣe níbi pèpéle òkúta a fi ń tẹ́lẹ̀ ilé ó jẹ́ mabu, píálì àti òkúta olówó iyebíye mìíràn. 7 Kọ́̀wúrà onídìí-odó ni a fi ń bu wáìnì fún wọn mu, ̀kọ̀̀kan wọn yàtọ̀ èkejì, wáìnì ọba pọ̀ púpọ̀, gẹ́gẹ́ ọba ṣe lawọ́ . 8 Gẹ́gẹ́ àṣẹ ọba a fi ààyè gba àlejò kọ̀̀kan láti mu ó ti fẹ́, nítorí ọba ti pàṣẹ fún gbogbo àwọn ti ń bu wáìnì láti fún ẹnìkọ̀̀kan wọ́n ṣe béèrè fún mọ.

9 Ayaba Faṣti náà ṣe àsè fún àwọn obìnrin ààfin ọba Ahaswerusi.

10 ọjọ́ keje, nígbà wáìnì inú ọba dùn, ó pàṣẹ fún Mehumani, Bista, Harbona, Bigta àti Abagta, Setari àti Karkasi, àwọn ìwẹ̀méje ń jíṣẹ́ fún Ahaswerusi. 11 wọn ayaba Faṣti síwájú rẹ̀, ti òun ti adé ọba rẹ̀, ó fi ẹwà rẹ̀ hàn àwọn ènìyàn àti àwọn ọlọ́, nítorí ó rẹwà. 12 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn ìránṣẹ́ jẹ́ iṣẹ́ ọba, ayaba Faṣti kọ̀ láti . Nígbà náà ni ọba bínú gidigidi, ìbínú náà pọ̀ jọjọ.

13 Gẹ́gẹ́ ìṣe rẹ̀ ìgbà gbogbo, ọba máa ń béèrè ̀rọ̀ lọ́wọ́ àwọn ó ìmọ̀ òfin àti ìdájọ́, ó sọ ́ fún àwọn amòye wọ́n mòye àkókò, 14 àwọn wọ́n súnmọ́ ọba àwọn wọ̀nyí ni Karṣina, Ṣetari, Admata, Tarṣiṣi, Meresi, Marsena àti Memukani, àwọn ọlọ́méje ti Persia àti Media wọ́n ṣe pàtàkì ọba, wọ́n tún ibi gíga ìjọba.

15 Ó béèrè , "ni a ṣe ayaba Faṣti gẹ́gẹ́ òfin? Nítorí tẹríba fún àṣẹ ọba Ahaswerusi àwọn ìwẹ̀ọba sọ fún un."

16 Memukani dáhùn níwájú ọba àti àwọn ọlọ́, "Ayaba Faṣti ti ṣe búburú, í ṣe ọba nìkan ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ọlọ́àti àwọn ènìyàn ó gbogbo agbègbè ilẹ̀ ọba Ahaswerusi. 17 Nítorí ìwà ayaba yìí yóò tàn ̀dọ̀ gbogbo àwọn obìnrin, bẹ́̀ ọkọ wọn yóò di gígàn lójú u wọn, wọn yóò sọ , ọba Ahaswerusi pàṣẹ á ayaba Faṣti síwájú òun, ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti . 18 ọjọ́ yìí gan an ni àwọn ọlọ́obìnrin Persia àti ti Media wọ́n ti gbọ́ nípa ìwà ayaba wọn yóò ṣe bẹ́̀ gbogbo àwọn ìjòyè ọba bákan náà. Àfojúdi àti àìnírẹ́pọ̀ lópin yóò .

19 "Nítorí náà, ó tọ́ lójú ọba, jẹ́ ó gbé àṣẹ ọba jáde, ó jẹ́ ó àkọsílẹ̀ pẹ̀òfin Persia àti Media, èyí le é parẹ́, Faṣti ó ṣe síwájú ọba Ahaswerusi. ọba fi oyè ayaba rẹ̀ fún ẹlòmíràn ó sàn ú lọ. 20 Nígbà náà a kéde òfin ọba ṣe gbogbo ilẹ̀ ìjọba rẹ̀, gbogbo àwọn obìnrin ni yóò bọ̀wọ̀ fún ọkọ wọn, láti ̀dọ̀ ẹni ó kéré títí ̀dọ̀ ẹni ńlá."

21 Ìmọ̀ràn yìí tẹ́ ọba àti àwọn ìjòyè rẹ̀ lọ́rùn, nítorí náà ọba ṣe gẹ́gẹ́ Memukani ṣé sọ. 22 Ó kọ̀ránṣẹ́ igun mẹ́rẹ̀̀rin ilẹ̀ ọba rẹ̀, ó kọ̀ìgbèríko kọ̀̀kan ìlànà wọ́n ṣe ń kọ̀, ó kọ̀àwọn ènìyàn kọ̀̀kan èdè wọn, Ó tẹnumọ́ èdè oníkálùkù olúkúlùkù ọkùnrin máa ṣàkóso ilé rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também