Pular para o conteúdo
Publicidade

Esteri 3

̀tẹ̀ Hamani láti pa àwọn Júù run

1 Lẹ́yìn àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí, ọba Ahaswerusi Hamani ọmọ Hammedata, ará Agagi lọ́, ọba gbé e ga, ó si fún un àga ọlá ó ju ti gbogbo àwọn ọlọ́tókù lọ. 2 Gbogbo àwọn ìjòyè ọba ó ẹnu-ọ̀ọba wọn kúnlẹ̀ wọ́n fi ọlá fun Hamani, nítorí ọba ti pàṣẹ èyí nípa tirẹ̀. Ṣùgbọ́n Mordekai kúnlẹ̀ tàbí bu ọlá fún un.

3 Nígbà náà ni àwọn ìjòyè ọba ó ẹnu-ọ̀béèrè lọ́wọ́ Mordekai , "Èéṣe ìwọ ṣe pa àṣẹ ọba mọ́." 4 ojoojúmọ́ ni wọ́n máa n sọ fún un ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti ṣe bẹ́̀. Nítorí náà, wọ́n sọ fún Hamani nípa rẹ̀ láti ó bóyá ó gba irú ìwà Mordekai ń yìí, nítorí ó ti sọ fún wọn Júù ni òun.

5 Nígbà Hamani i Mordekai kúnlẹ̀ tàbí bu ọlá fún òun, ó bínú. 6 Síbẹ̀ mọ irú ènìyàn Mordekai jẹ́, ó kẹ́gàn láti pa Mordekai nìkan. Dípò bẹ́̀ Hamani ń láti pa gbogbo ènìyàn Mordekai run, àwọn Júù jákèjádò gbogbo ìjọba Ahaswerusi.

7 ọdún kejìlá ọba Ahaswerusi, oṣù kìn-ín-ní, èyí ni oṣù Nisani, wọ́n da puri (èyí í ṣe, ìbò) iwájú Hamani láti yan ọjọ́ kan àti oṣù, ìbò náà wáyé oṣù kejìlá, oṣù Addari.

8 Nígbà náà ni Hamani sọ fún ọba Ahaswerusi , "Àwọn ènìyàn kan wọ́n fọ́nká wọ́n túká ara àwọn ènìyàn gbogbo àgbáyé ìjọba rẹ̀ ìṣe wọn yàtọ̀ ti gbogbo àwọn tókù wọn pa òfin ọba mọ́; èyí í ṣe ìfẹ́ ọba láti gbà fún wọn bẹ́̀. 9 ó tẹ́ ọba lọ́rùn, a gbé òfin kan jáde yóò pa wọ́n run, èmi yóò fi ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) tálẹ́ǹtì fàdákà sínú ìṣúra ọba fún àwọn ọkùnrin wọn o ṣe iṣẹ́ náà."

10 Nítorí náà, ọba bọ́ òrùka èdìdì ó ìka rẹ̀, ó fi fún Hamani ọmọ Hammedata, ará Agagi, ̀àwọn Júù. 11 Ọba sọ fún Hamani , "Pa owó náà mọ́, o ṣe ohun ó ́ fún àwọn ènìyàn náà."

12 Nígbà ó di ọjọ́ kẹtàlá oṣù kìn-ín-ní àkọ́kọ́, wọ́n pe àwọn akọ̀ọba jọ. Wọ́n kọ ́ ìlànà ìgbèríko kọ̀̀kan ṣe ń kọ̀, ó kọ̀àwọn ènìyàn kọ̀̀kan èdè wọn gbogbo èyí Hamani ti pàṣẹ àwọn akọ̀ọba, baálẹ̀ ìgbèríko kọ̀̀kan àti àwọn ọlọ́àwọn onírúurú ènìyàn. A kọ èyí orúkọ ọba Ahaswerusi fúnra rẹ̀ ó fi òrùka ọba ṣe èdìdì i rẹ̀. 13 A fi ìwé náà ránṣẹ́ gbogbo àwọn ìgbèríko ọba pẹ̀àṣẹ láti parun, láti pa gbogbo àwọn Júù èwe àti àgbà, obìnrin àti àwọn ọmọ wẹ́wẹ́—ọjọ́ kan wọn parẹ́, ọjọ́ kẹtàlá oṣù kejìlá, oṣù Addari a àwọn ohun ìní wọn. 14 àdàkọ ìwé náà a tẹ̀ ́ jáde òfin gbogbo ìgbèríko ó di mọ̀ fún àwọn ènìyàn ìlú nítorí wọ́n le múra fún ọjọ́ náà.

15 Àwọn ìránṣẹ́ náà jáde, wọ́n tẹ̀síwájú nípa àṣẹ ọba, ìkéde náà jáde ilé ìṣọ́ ti Susa. Ọba àti Hamani jókòó wọ́n ń mu, ṣùgbọ́n ìlú Susa nínú ìdààmú.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também