Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 21

Àwọn ará Gibeoni gba ̀san

1 Ìyàn kan lọ́jọ́ Dafidi ọdún mẹ́ta, láti ọdún ọdún; Dafidi béèrè lọ́dọ̀ Olúwa, Olúwa , "Nítorí ti Saulu ni, àti nítorí ilé rẹ̀ ó kún fún ̀jẹ̀, nítorí ó pa àwọn ará Gibeoni."

2 Ọba pe àwọn ará Gibeoni, ó wọn sọ̀rọ̀; àwọn ará Gibeoni í ṣe ̀kan nínú àwọn ọmọ Israẹli, ṣùgbọ́n wọ́n jẹ́ àwọn ó nínú àwọn ọmọ Amori; àwọn ọmọ Israẹli ti búra fún wọn, Saulu ń ̀àti pa wọ́n ìtara rẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli àti Juda. 3 Dafidi bi àwọn ará Gibeoni léèrè , "ni èmi ó ṣe fún un yín? Àti kín ni èmi ó fi ṣe ètùtù, ̀yin súre fún ilẹ̀ ìní Olúwa?"

4 Àwọn ará Gibeoni fún un , "í ṣe ̀rọ̀ fàdákà tàbí wúrà láàrín wa àti Saulu tàbí ìdílé rẹ̀, bẹ́̀ ni a fẹ́ pa ẹnìkan Israẹli."

Dafidi , "Èyí ̀yin ni èmi ó ṣe?"

5 Wọ́n fún ọba , "Ọkùnrin ó run , ó láti pa rẹ́ ki a níbikíbi nínú gbogbo agbègbè Israẹli. 6 ọkùnrin méje nínú àwọn ọmọ rẹ̀ fún , àwa ó so wọ́n rọ̀ fún Olúwa Gibeah ti Saulu ẹni Olúwa ti yàn."

Ọba , "Èmi ó fi wọ́n fún yín."

Síso Àwọn Ènìyàn Saulu Méje Rọ̀

7 Ṣùgbọ́n ọba Mefiboṣeti , ọmọ Jonatani, ọmọ Saulu, nítorí ìbúra Olúwa ó láàrín Dafidi àti Jonatani ọmọ Saulu. 8 Ọba àwọn ọmọkùnrin méjèèjì Rispa ọmọbìnrin Aiah fún Saulu, àní Ammoni àti Mefiboṣeti àwọn ọmọkùnrin márààrún ti Merabu, ọmọbìnrin Saulu, àwọn ó fún Adrieli ọmọ Barsillai ará Mehola. 9 Ó fi wọ́n àwọn ará Gibeah lọ́wọ́, wọ́n so wọ́n rọ̀ lórí òkè níwájú Olúwa: àwọn méjèèjì ṣubú lẹ́̀kan, a pa wọ́n ìgbà ìkórè, ìbẹ̀rẹ̀, ìkórè ọkà barle.

10 Rispa ọmọbìnrin Aiah aṣọ ̀fọ̀ kan, ó tẹ́ fún ará rẹ̀ lórí àpáta ìbẹ̀rẹ̀ ìkórè, títí omi fi wọn lára láti ̀run , jẹ́ àwọn ẹyẹ ojú ̀run wọn lọ́sàn, tàbí àwọn ẹranko igbó lóru. 11 A ro èyí, Rispa ọmọbìnrin Aiah obìnrin Saulu ṣe, fún Dafidi. 12 Dafidi lọ ó egungun Saulu, àti egungun Jonatani ọmọ rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọkùnrin Jabesi Gileadi, àwọn ó wọn kúrò ìta Beti-Ṣani, níbi àwọn Filistini gbé so wọ́n rọ̀, nígbà àwọn Filistini pa Saulu Gilboa. 13 Ó egungun Saulu àti egungun Jonatani ọmọ rẹ̀ láti ibẹ̀ náà ; wọ́n egungun àwọn a ti so rọ̀ jọ.

14 Wọ́n sin egungun Saulu àti ti Jonatani ọmọ rẹ̀ ilé Benjamini, Ṣela, nínú ibojì Kiṣi baba rẹ̀, wọ́n ṣe gbogbo èyí ọba paláṣẹ, lẹ́yìn èyí ni Ọlọ́run si gba ̀bẹ̀ nítorí ilẹ̀ náà.

Ìṣẹ́gun lórí Filistini

15 Ogun tún láàrín àwọn Filistini àti Israẹli; Dafidi sọ̀kalẹ̀, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀rẹ̀, ó àwọn Filistini , ó rẹ Dafidi. 16 Iṣbi-Benobu jẹ́ ̀kan nínú àwọn Rafa, ẹni ̀kọ̀ rẹ̀ wọn ̀́dúnrún (300) ṣékélì idẹ, ó sán idà tuntun, ó gbèrò láti pa Dafidi. 17 Ṣùgbọ́n Abiṣai ọmọ Seruiah ràn án lọ́wọ́, ó kọlu Filistini náà, ó pa á. Nígbà náà ni àwọn ìránṣẹ́ Dafidi búra fún un , "Ìwọ yóò tún wa jáde lọ ibi ìjà mọ́ ìwọ ṣe pa iná Israẹli."

18 21.18-22: 1Ki 20.4-8. Lẹ́yìn èyí, ìjà kan tún láàrín àwọn Israẹli àti àwọn Filistini Gobu, nígbà náà ni Sibekai ará Huṣati pa Safu, ẹni í ṣe ̀kan nínú àwọn Rafa.

19 Ìjà kan tún Gobu láàrín àwọn Israẹli àti àwọn Filistini, Elhanani ọmọ Jairi ará Bẹtilẹhẹmu pa arákùnrin Goliati ará Gitti, ẹni ̀̀kọ̀ rẹ̀ dàbí ìdábùú apásá ìhunṣọ.

20 Ìjà kan tún Gati, ọkùnrin kan ó ga púpọ̀, ó ìka mẹ́ọwọ́ kan, àti ọmọ ẹsẹ̀ mẹ́ẹsẹ̀ kan, àpapọ̀ rẹ̀ jẹ́ mẹ́rìnlélógún; a òun náà Rafa. 21 Nígbà òun pe Israẹli ìjà. Jonatani ọmọ Ṣimea arákùnrin Dafidi pa á.

22 Àwọn mẹ́rẹ̀̀rin wọ̀nyí ni ìran Rafa Gati, wọ́n ti ọwọ́ Dafidi ṣubú àti ọwọ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também