Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 20

Ṣeba ṣọ̀tẹ̀ Dafidi

1 Ọkùnrin Beliali kan ń bẹ níbẹ̀ orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ṣeba ọmọ Bikri ará Benjamini; ó fún ìpè ó ,

"Àwa ipa nínú Dafidi,

bẹ́̀ ni àwa ni ìní nínú ọmọ Jese!

olúkúlùkù ọkùnrin lọ àgọ́ rẹ̀, ̀yin Israẹli!"

2 Gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli lọ kúrò lẹ́yìn Dafidi, wọ́n ń tọ́ Ṣeba ọmọ Bikri lẹ́yìn, ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin Juda fi ara mọ́ ọba wọn láti odò Jordani títí ó fi Jerusalẹmu.

3 Dafidi ilé rẹ̀ Jerusalẹmu; ọba àwọn obìnrin mẹ́wàá í ṣe àlè rẹ̀, àwọn ó ti fi sílẹ̀ láti máa ṣọ́ ilé, Ó wọn mọ́ ilé, ó ń bọ́ wọn, ṣùgbọ́n tún wọlé tọ̀ wọ́n mọ́. A wọn mọ́ títí di ọjọ́ ikú wọn, wọ́n opó.

Joabu fi idà gún Amasa, ó

4 Ọba fún Amasa , "Pe àwọn ọkùnrin Juda fún mi ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́ta òní, ìwọ náà o níhìn-ín yìí." 5 Amasa lọ láti pe àwọn ọkùnrin Juda; ṣùgbọ́n ó dúró pẹ́ ju àkókò a fi fún un.

6 Dafidi fún Abiṣai , "Nísinsin yìí Ṣeba ọmọ Bikri yóò ṣe ibi ju ti Absalomu lọ; ìwọ àwọn ìránṣẹ́ olúwa rẹ, o lépa rẹ̀, ó ba à ìlú olódi wọ̀, ó bọ́ lọ́wọ́ wa." 7 Àwọn ọmọkùnrin Joabu jáde tọ̀ ́ lọ, àti àwọn Kereti, àti àwọn Peleti, àti gbogbo àwọn ọkùnrin alágbára, wọ́n ti Jerusalẹmu jáde lọ, láti lépa Ṣeba ọmọ Bikri.

8 Nígbà wọ́n ibi òkúta ńlá ó Gibeoni, Amasa ṣáájú wọn, Joabu di àmùrè agbádá rẹ̀ ó wọ̀, ó sán idà rẹ̀ mọ́ ìdí, nínú àkọ̀ rẹ̀, ó ti ń lọ, ó yọ́ jáde.

9 Joabu bi Amasa léèrè , "Àlàáfíà ha kọ́ ni , ìwọ arákùnrin mi?" Joabu na ọwọ́ ̀tún rẹ̀, di Amasa irùngbọ̀n láti fi ẹnu ó lẹ́nu. 10 Ṣùgbọ́n Amasa kíyèsi idà ń bẹ lọ́wọ́ Joabu, bẹ́̀ ni òun fi gún un ikùn, ìfun rẹ̀ sílẹ̀, òun tún gún un mọ́, Amasa . Joabu àti Abiṣai arákùnrin rẹ̀ lépa Ṣeba ọmọ Bikri.

Joabu lépa Seba

11 ̀kan nínú àwọn ̀dọ́mọdékùnrin ó lọ́dọ̀ Joabu dúró Amasa, ó , "Ta ni ẹni ó fẹ́ràn Joabu? Ta ni ó ń ṣe ti Dafidi, ó máa tọ Joabu lẹ́yìn." 12 Amasa ń yíràá nínú ̀jẹ̀ láàrín ̀. Ọkùnrin náà i gbogbo ènìyàn dúró í, ó gbé Amasa kúrò lójú ̀lọ sínú igbó, ó fi aṣọ ó, nígbà ó i ẹnikẹ́ni ó ̀dọ̀ rẹ̀, á dúró. 13 Nígbà ó gbé Amasa kúrò lójú ̀gbogbo ènìyàn tọ Joabu lẹ́yìn láti lépa Ṣeba ọmọ Bikri.

Wọ́n Ṣeba lórí

14 Ṣeba kọjá nínú gbogbo ̀Israẹli Abeli-Beti-Maaka, àti gbogbo àwọn ará Beri; wọ́n ara wọn jọ, wọ́n tọ̀ ́ lẹ́yìn pẹ̀. 15 Wọ́n , wọ́n Ṣeba Abeli-Beti-Maaka, wọ́n mọ odi ti ìlú náà, odi náà dúró ti odi ìlú náà, gbogbo ènìyàn ń bẹ lọ́dọ̀ Joabu ń gbìyànjú láti ògiri náà lulẹ̀. 16 Obìnrin ọlọ́gbọ́n kan kígbe sókè láti ìlú náà , "Fetísílẹ̀! Fetísílẹ̀! Èmi bẹ̀ yín, sọ fún Joabu , Súnmọ́ ìhín yìí èmi ó a sọ̀rọ̀.’ " 17 Nígbà òun súnmọ́ ̀dọ̀ rẹ̀, obìnrin náà , "Ìwọ ni Joabu ?"

Òun dáhùn , "Èmi náà ni."

Obìnrin náà fún un , "Gbọ́ ̀rọ̀ ìránṣẹ́bìnrin rẹ."

Òun dáhùn , "Èmi ń gbọ́."

18 Ó sọ̀rọ̀ , "Wọ́n ti ń ṣáájú , Gba ìdáhùn rẹ Abeli,bẹ́̀ ni wọ́n parí ̀ràn náà. 19 Èmi ni ̀kan nínú àwọn ẹni àlàáfíà àti olóòtítọ́ Israẹli, ìwọ ń ̀láti pa ìlú kan run ó jẹ́ ìyá Israẹli, èéṣe ìwọ ó fi gbé ìní Olúwa ."

20 Joabu dáhùn , "a i, a i lọ́dọ̀ mi èmi gbé tàbí èmi parun. 21 ̀ràn náà bẹ́̀; ṣùgbọ́n ọkùnrin kan láti òkè Efraimu, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ṣeba, ọmọ Bikri, ni ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè ọba, àní Dafidi: fi òun nìkan ṣoṣo wa lọ́wọ́, èmi ó fi ìlú sílẹ̀."

Obìnrin náà fún Joabu , "ó, orí rẹ̀ ni a ó sọ láti inú odi ."

22 Obìnrin náà ìmọ́ràn rẹ̀ tọ gbogbo àwọn ènìyàn náà, wọ́n bẹ Ṣeba ọmọ Bikri lórí, wọ́n sọ ́ Joabu. Òun fún ìpè, wọ́n túká ìlú náà, olúkúlùkù àgọ́ rẹ̀. Joabu padà lọ Jerusalẹmu àti sọ́dọ̀ ọba.

Àwọn ìránṣẹ́ Dafidi

23 20.23-26: 2Sa 8.15-18; 24.2. Joabu ni olórí gbogbo ogun Israẹli;

Benaiah ọmọ Jehoiada jẹ́ olórí àwọn Kereti, àti ti àwọn Peleti.

24 Adoniramu jẹ́ olórí àwọn agbowó òde;

Jehoṣafati ọmọ Ahiludi jẹ́ olùkọsílẹ̀ ohun ó ń ṣẹlẹ̀ ìlú.

25 Ṣefa jẹ́ akọ̀;

Sadoku àti Abiatari ni àwọn àlùfáà.

26 Ira pẹ̀, ará Jairi ni ń ṣe àlùfáà lọ́dọ̀ Dafidi.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também