Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Samuẹli 14

Absalomu padà si Jerusalẹmu

1 Joabu ọmọ Seruiah kíyèsi i, ọkàn ọba Absalomu. 2 Joabu ránṣẹ́ Tekoa, ó ọlọ́gbọ́n obìnrin kan láti ibẹ̀ , ó fún un , "Èmi bẹ̀ ́, ṣe ẹni ń ṣọ̀fọ̀, o fi aṣọ ̀fọ̀ sára, o ṣe fi òróró pa ara, o dàbí obìnrin ti ó ti ń ṣọ̀fọ̀ fún òkú lọ́jọ́ púpọ̀. 3 o tọ ọba , o sọ fún un gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ yìí." Joabu fi ̀rọ̀ lẹ́nu.

4 Nígbà obìnrin àrá Tekoa ń fẹ́ sọ̀rọ̀ fún ọba, ó wólẹ̀, ó dojúbolẹ̀, o bu ọlá fún un, o , "Ọba, gbà mi."

5 Ọba bi í léèrè , "Kín ni o ṣe ́?"

Òun dáhùn , "Nítòótọ́ opó ni èmi ń ṣe, ọkọ mi . 6 Ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ ti ọmọkùnrin méjì, àwọn méjèèjì jọ lóko, si ẹni yóò wọ́n, èkínní lu èkejì, ó pa á. 7 ó, gbogbo ìdílé dìde ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀, wọ́n , Fi ẹni ó pa arákùnrin rẹ fún wa, àwa ó pa á ipò ̀arákùnrin rẹ̀ ó pa, àwa ó pa àrólé náà run pẹ̀.Wọn ó pa iná mi ó , wọn yóò fi orúkọ tàbí ẹni ó sílẹ̀ fún ọkọ mi ayé."

8 Ọba fún obìnrin náà , "Lọ ilé rẹ̀, èmi ó kìlọ̀ nítorí rẹ."

9 Obìnrin ará Tekoa náà fún ọba , "Olúwa mi, ọba, jẹ́ ̀ṣẹ̀ náà lórí mi, àti lórí ìdílé baba ; ọba àti ìtẹ́ rẹ̀ ó jẹ́ aláìlẹ́bi."

10 Ọba , "Ẹnikẹ́ni ó sọ̀rọ̀ , ẹni náà tọ̀ , òun yóò tọ́ mọ́."

11 Ó , "Èmi bẹ̀ ́ jẹ́ ọba ó rántí Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, olùgbẹ̀san ̀jẹ̀ ṣe ipá láti ṣe ìparun, wọn o a pa ọmọ mi!"

Òun , "Olúwa ti ń bẹ láààyè ̀kan nínú irun orí ọmọ rẹ ki yóò bọ sílẹ̀."

̀bẹ̀ ti Absalomu

12 Obìnrin náà , "Èmí bẹ̀ ́, jẹ́ ìránṣẹ́bìnrin rẹ sọ̀rọ̀ kan fún olúwa mi ọba."

Òun si , "Máa ."

13 Obìnrin náà , "Nítorí kín ni ìwọ ṣe ro irú nǹkan yìí àwọn ènìyàn Ọlọ́run? Nítorí sísọ nǹkan yìí ọba ̀bi, nítorí ọba ìsáǹsá rẹ̀ bọ̀ ilé. 14 Nítorí àwa ó à , a ó dàbí omi a sílẹ̀ a ṣàjọ mọ́; nítorí Ọlọ́run ti gbà ̀rẹ̀, ó ti ṣe ̀a a ìsáǹsá rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ rẹ.

15 "Ǹjẹ́ nítorí náà ni èmi ṣe sọ nǹkan yìí fún olúwa mi ọba, ó tilẹ̀ jẹ́ àwọn ènìyàn ti dẹ́rùbà ; ìránṣẹ́bìnrin rẹ , Ǹjẹ́ èmi ó sọ fún ọba; ó bẹ́̀ ọba yóò ṣe ìfẹ́ ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ fún un. 16 Nítorí ọba ò gbọ́, láti gbà ìránṣẹ́bìnrin rẹ sílẹ̀ lọ́wọ́ ọkùnrin náà ó ń fẹ́ èmi àti ọmọ mi pẹ̀kúrò nínú ilẹ̀ ìní Ọlọ́run.

17 "Ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ , Ǹjẹ́ ̀rọ̀ ọba olúwa mi yóò jásí ìtùnú; nítorí angẹli Ọlọ́run bẹ́̀ ni olúwa mi ọba láti mọ rere àti búburú: Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò pẹ̀rẹ.’ "

Dafidi mọ̀ Joabu ni ó ṣe èyí

18 Ọba dáhùn, ó fún obìnrin náà , "ṣe fi nǹkan èmi ó béèrè lọ́wọ́ rẹ pamọ́ fún mi, èmi bẹ̀ ́."

Obìnrin náà , "Jẹ́ olúwa mi ọba máa ?"

19 Ọba , "Ọwọ́ Joabu ha pẹ̀rẹ nínú gbogbo èyí?"

Obìnrin náà dáhùn ó , "̀rẹ ti ń bẹ láààyè, olúwa mi ọba, ìyípadà ọwọ́ ̀tún, tàbí ọwọ́ òsì nínú gbogbo èyí olúwa mi ọba ti , nítorí Joabu ìránṣẹ́ rẹ, òun ni ó rán mi, òun ni ó fi gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí ìránṣẹ́bìnrin rẹ lẹ́nu. 20 Láti irú ̀rọ̀ wọ̀nyí ni Joabu ìránṣẹ́ rẹ ṣe ṣe nǹkan yìí: olúwa mi gbọ́n, gẹ́gẹ́ ọgbọ́n angẹli Ọlọ́run, láti mọ gbogbo nǹkan ń bẹ̀ ayé."

Absalomu padà ilé

21 Ọba fún Joabu , "ó, èmi ó ṣe nǹkan yìí, nítorí náà lọ, o ọmọdékùnrin náà Absalomu padà ."

22 Joabu wólẹ̀ ó dojú rẹ̀ bolẹ̀, ó tẹríba fún un, ó súre fún ọba. Joabu , "Lónìí ni ìránṣẹ́ rẹ mọ̀ , èmi oore-ọ̀fẹ́ gbà lójú rẹ, olúwa mi, ọba, nítorí ọba ṣe ìfẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀."

23 Joabu dìde, ó lọ Geṣuri, ó Absalomu Jerusalẹmu. 24 Ọba , "Jẹ́ ó yípadà lọ ilé rẹ̀, ṣe jẹ́ ó ojú mi." Absalomu yípadà ilé rẹ̀, ojú ọba.

Ẹwà Absalomu àti àwọn ọmọ rẹ̀

25 arẹwà kan gbogbo Israẹli à yìn Absalomu: láti àtẹ́lẹsẹ̀ rẹ̀ títí àtàrí rẹ̀ àbùkù kan lára rẹ̀. 26 Nígbà ó rẹ́ irun orí rẹ̀ (nítorí lọ́dọọdún ni òun máa ń rẹ́ . Nígbà ó wúwo fún un, òun a máa rẹ́ ) òun wọn irun orí rẹ̀, ó jásí igba ṣékélì nínú òsùwọ̀n ọba.

27 A ọmọkùnrin mẹ́ta fún Absalomu àti ọmọbìnrin kan ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Tamari: òun jẹ́ obìnrin ó lẹ́lójú.

Ọgbọ́n ̀wẹ́ Absalomu

28 Absalomu gbé ni ọdún méjì Jerusalẹmu ojú ọba. 29 Absalomu ránṣẹ́ Joabu, láti rán an ọba, ṣùgbọ́n òun fẹ́ sọ́dọ̀ rẹ̀; ó ránṣẹ́ lẹ́̀kejì òun fẹ́ . 30 Ó fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "ó, oko Joabu gbé ti èmi, ó ọkà barle níbẹ̀; lọ ti iná bọ̀ ́." Àwọn ìránṣẹ́ Absalomu tiná bọ oko náà.

31 Joabu dìde, ó tọ Absalomu ilé, ó fún un , "Èéṣe àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ fi tiná bọ oko mi?"

32 Absalomu Joabu lóhùn , "ó, èmi ránṣẹ́ , , níhìn-ín yìí, èmi ó rán lọ sọ́dọ̀ ọba, láti béèrè , "ni èmi ti Geṣuri si? Ìbá sàn fún ó ṣe èmi lọ́hùn ún síbẹ̀!" Ǹjẹ́ nísinsin yìí jẹ́ èmi lọ síwájú ọba ó ṣe ̀bi ń bẹ nínú mi, ó pa ."

33 Joabu tọ ọba , ó fún un: ó ránṣẹ́ pe Absalomu, òun sọ́dọ̀ ọba, ó tẹríba fún un, ó dojú rẹ̀ bolẹ̀ níwájú ọba, ọba fi ẹnu ko Absalomu lẹ́nu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também